Home / Art / Àṣà Oòduà / Arákùnrin kan ni ó na ìyàwó rè, tí ó sì ba àwò ara ré je.

Arákùnrin kan ni ó na ìyàwó rè, tí ó sì ba àwò ara ré je.

Arákùnrin kan ni a gbó wípé ó na ìyàwó rè tí ó sì dá àpá si lára, ládúrú bí won ti se n kó wa ní èkó lórí bí a se le gbé lókoláya tó.

Bí ó tilè jé wípé aláse ni oko lórí aya rè ,ìyan kò so wípé kí ó so ìyàwó rè di bàrà kí ó so ó di bènbé ìlú, bí oko se láse lórí aya ni ìyàwó náà láse lórí oko.
Èyin okùnrin wa e jòwó e jé kí a máa fi ìfé bá àwon aya wa gbé, nítorí àwon ni alásirí wa, ìròrùn igi náà ni ìròrùn eye, èyí túmò sí wípé ìròrùn aya ní ìròrùn oko rè.
E jé kí á dékun ìjà láàrin lókoláya( say no domestic violence).

About Awoyemi Bamimore

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

Omisore

Àwàdà kẹrí-Kẹrì ni àwọn kọmití tó ní mi ò lè díje du ipò gómìnà APC ni 2026 n ṣe – Omisore

Yínká Àlàbí Awọn kọmiti to n ṣe àyẹ̀wò awọn oludije du ipo gomina labẹ ẹgbẹ́ oselu APC ti ja igbakeji gomina tẹlẹ ni ipinle Osun, Alagba Iyiola Omisore ati awọn mẹfa miiran.Wọn ni iwe wọn ko pe lati dije du ipo gomina ipinlẹ naa. Awọn mẹfẹẹfa to ku naa ni – Babatunde Oralusi, Oyedotun Babayemi, Dr. Akin Ogunbiyi, Benedict Alabi, Adegoke Rasheed Okiki, ati Senator Babajide Omoworare.Iyiola Omisore ni awada Kẹri-Kẹri ni awọn kọmiti naa n se nitori ti wọn ...