Home / Art / Àṣà Oòduà / Oòni ti ìlú ilé-ifè darapò mó àwon mùsùlúmí ilé-ifè láti kírun ní ojó odún iléyà tí a mò sí Eid-el kabir.

Oòni ti ìlú ilé-ifè darapò mó àwon mùsùlúmí ilé-ifè láti kírun ní ojó odún iléyà tí a mò sí Eid-el kabir.

Gégé bí a se mò wípé àwon omo léyìn músùlùmí sèsè se àsekágbá odún won ní léyìn tí won ti gba ààwè séyìn léyìn bí osù mejì àti òsè mélòó sèyìn.

Oba Adeyeye Enitan Ogunwusi ti darapò mó àwon músúlúmi láti kírun papò ní ojó òdún yí, ìyàlénu nlá gbáà ni èyí jé fún àwon èèyàn.

Òtító kúkú ni wípé Oba kò ní èsìn kan ní pàtó, àti wípé Adeyeye jé kí a mò wípé bí oba se ba lórí ohun gbogbo ni Olódùmarè náa se ba lórí oba.
Èyí tí oba se yí jé kí a mò wípé òkan soso ni olórun, bí ó tilè jé wípé bí a se ñ kígbe pèé ló yàtò.

About Awoyemi Bamimore

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

“Ìyálóde, Eléékò & The Heavenly Companions: Discover the Mysterious Classes of Egbe in Yoruba Tradition”

Classes of Egbe (Heavenly Mate of Every Human) Also known as Alaragbo in some areas of Yoruba land, Egbe is generally more associated with children than with adults according to Eji-Ogbe. Based on the character traits of human on Earth, the Yoruba have classified Egbe into different categories. Ìyálóde Ìyálóde is regarded as the leader of Egbe on Earth. Leadership quality is most evident characteristic of this class of Egbe. Going by the name, it may appear that only females ...