Home / Art / Àṣà Oòduà / Arákùnrin kan ni ó na ìyàwó rè, tí ó sì ba àwò ara ré je.

Arákùnrin kan ni ó na ìyàwó rè, tí ó sì ba àwò ara ré je.

Arákùnrin kan ni a gbó wípé ó na ìyàwó rè tí ó sì dá àpá si lára, ládúrú bí won ti se n kó wa ní èkó lórí bí a se le gbé lókoláya tó.

Bí ó tilè jé wípé aláse ni oko lórí aya rè ,ìyan kò so wípé kí ó so ìyàwó rè di bàrà kí ó so ó di bènbé ìlú, bí oko se láse lórí aya ni ìyàwó náà láse lórí oko.
Èyin okùnrin wa e jòwó e jé kí a máa fi ìfé bá àwon aya wa gbé, nítorí àwon ni alásirí wa, ìròrùn igi náà ni ìròrùn eye, èyí túmò sí wípé ìròrùn aya ní ìròrùn oko rè.
E jé kí á dékun ìjà láàrin lókoláya( say no domestic violence).

About Awoyemi Bamimore

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

“Ìyálóde, Eléékò & The Heavenly Companions: Discover the Mysterious Classes of Egbe in Yoruba Tradition”

Classes of Egbe (Heavenly Mate of Every Human) Also known as Alaragbo in some areas of Yoruba land, Egbe is generally more associated with children than with adults according to Eji-Ogbe. Based on the character traits of human on Earth, the Yoruba have classified Egbe into different categories. Ìyálóde Ìyálóde is regarded as the leader of Egbe on Earth. Leadership quality is most evident characteristic of this class of Egbe. Going by the name, it may appear that only females ...