Home / Art / Àṣà Oòduà / Asòfin egbé APC, tí a mò sí Hon. Timothy Owoeye, fi èjè wè ní òrú gànjó.

Asòfin egbé APC, tí a mò sí Hon. Timothy Owoeye, fi èjè wè ní òrú gànjó.

Owó pálábá Asòfin egbé APC tí ó sì jé gbòógì , tí ó sì jé asojú ilé ìgbìmò asòfin tí Ilésà ní ìpínlè Osun, ni owó bá nígbà tí ó n fi èjè wè ní àrin òru tí ó sì n be àwon ará agbègbè náà kí won má se bínú.

Tí ó bá ti è jé wípé ibò míràn ni ó ti wè é ni ò se é se kí owó pálábá rè má ségi súgbón òkété rè kò bímo etílé àrin ojà ni ó ti n fi wè.
Èyin ìjoba wa èbè la bèyín kí e má se jé kí òsèlú gba omolúàbí.

About Awoyemi Bamimore

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

yemoja 2026

Yoruba Yemoja float with 10,000 Litres of water by Mocidade Alegre Won the São Paulo Carnival 2026 in Brazil!

This majestic allegorical float, a viral sensation during the parade, featured Yemoja (Iemanjá) Yemoja was powerfully incorporated because the enredo “Malunga Léa – Rapsódia de uma Deusa Negra” was a heartfelt tribute to the late legendary Brazilian actress Léa Garcia (1930–2023). A pioneering African icon in theater, film, and TV (famous for roles like in Escrava Isaura and her work with Teatro Experimental do Negro). The theme celebrated her as a “deusa negra” (“Black” Goddess): her resilience, ancestral strength, female ...