Home / Art / Àṣà Oòduà / Iba Gani Adams pàdánù baba rè .

Iba Gani Adams pàdánù baba rè .

Baba Ààre Ona-kakanfo ti ilè Yorùbá tí a mò sí Iba Gani Adams ti lo.
Pa Lamidi Adams tí ó ta téru nípà ní ojó Àbáméta ní ilé ìwòsàn aládáni ní ìpínlè Eko, baba kú ní ìgbà tí won fé pé ogórin odún.
Nínú ìròyìn tí a gbó, a gbó wípé baba ní àwon oko agbèrò tí won dá ni, ní Oturkpo ní ìpínlè Benue kí ó tó di wípé won darapò mó àwon Desmony Nig. Ltd.
Won sisé pèlú àwon Desmony Nigeria Ltd, ilé-isé àwon Italy ní ìgbà kékeré gégé bí olórí àwon awakò kí won to dá ti won sílè.
Kí Elédúà té won sí aféfé rere.

About Awoyemi Bamimore

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

Lati Ọwọ Aworosaṣa Moyọ Okediji

Cultural War Rages on: Africa’s Civilizations Are Being Erased—who Will Teach African Artists?

AFRICAN AESTHETICS Many universities in the West are developing core curriculum programs focused on “Western Civilization,” while increasingly purging African, African Diaspora, Asian, and other civilizations from their programs. The West focusing on Western Civilization is appropriate. The days of African and African Diaspora Studies seem numbered. At the same time, Africana artists are producing contemporary works like never before. What are these Africana artists going to read? Are they going to study Western Civilization only, without any understanding of ...