Home / Art / Àṣà Oòduà / Iba Gani Adams pàdánù baba rè .

Iba Gani Adams pàdánù baba rè .

Baba Ààre Ona-kakanfo ti ilè Yorùbá tí a mò sí Iba Gani Adams ti lo.
Pa Lamidi Adams tí ó ta téru nípà ní ojó Àbáméta ní ilé ìwòsàn aládáni ní ìpínlè Eko, baba kú ní ìgbà tí won fé pé ogórin odún.
Nínú ìròyìn tí a gbó, a gbó wípé baba ní àwon oko agbèrò tí won dá ni, ní Oturkpo ní ìpínlè Benue kí ó tó di wípé won darapò mó àwon Desmony Nig. Ltd.
Won sisé pèlú àwon Desmony Nigeria Ltd, ilé-isé àwon Italy ní ìgbà kékeré gégé bí olórí àwon awakò kí won to dá ti won sílè.
Kí Elédúà té won sí aféfé rere.

About Awoyemi Bamimore

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

“Ìyálóde, Eléékò & The Heavenly Companions: Discover the Mysterious Classes of Egbe in Yoruba Tradition”

Classes of Egbe (Heavenly Mate of Every Human) Also known as Alaragbo in some areas of Yoruba land, Egbe is generally more associated with children than with adults according to Eji-Ogbe. Based on the character traits of human on Earth, the Yoruba have classified Egbe into different categories. Ìyálóde Ìyálóde is regarded as the leader of Egbe on Earth. Leadership quality is most evident characteristic of this class of Egbe. Going by the name, it may appear that only females ...