Home / Art / Àṣà Oòduà / Asòfin egbé APC, tí a mò sí Hon. Timothy Owoeye, fi èjè wè ní òrú gànjó.

Asòfin egbé APC, tí a mò sí Hon. Timothy Owoeye, fi èjè wè ní òrú gànjó.

Owó pálábá Asòfin egbé APC tí ó sì jé gbòógì , tí ó sì jé asojú ilé ìgbìmò asòfin tí Ilésà ní ìpínlè Osun, ni owó bá nígbà tí ó n fi èjè wè ní àrin òru tí ó sì n be àwon ará agbègbè náà kí won má se bínú.

Tí ó bá ti è jé wípé ibò míràn ni ó ti wè é ni ò se é se kí owó pálábá rè má ségi súgbón òkété rè kò bímo etílé àrin ojà ni ó ti n fi wè.
Èyin ìjoba wa èbè la bèyín kí e má se jé kí òsèlú gba omolúàbí.

About Awoyemi Bamimore

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

What is Àdìmù?

A few of my friends and students in the diaspora had asked me this question countless times, and I think it’s high time we discussed it.Please note that this is not an attempt to discredit or invalidate any practice or belief; this piece is just for us to educate one another.Now, in the Yoruba language, what does Adimu mean, or where does it originate from?Àdimu means “To hold.”The full word is Adimula, which means “to hold and prosper.”So, where does ...