Home / Art / Àṣà Oòduà / Asòfin egbé APC, tí a mò sí Hon. Timothy Owoeye, fi èjè wè ní òrú gànjó.

Asòfin egbé APC, tí a mò sí Hon. Timothy Owoeye, fi èjè wè ní òrú gànjó.

Owó pálábá Asòfin egbé APC tí ó sì jé gbòógì , tí ó sì jé asojú ilé ìgbìmò asòfin tí Ilésà ní ìpínlè Osun, ni owó bá nígbà tí ó n fi èjè wè ní àrin òru tí ó sì n be àwon ará agbègbè náà kí won má se bínú.

Tí ó bá ti è jé wípé ibò míràn ni ó ti wè é ni ò se é se kí owó pálábá rè má ségi súgbón òkété rè kò bímo etílé àrin ojà ni ó ti n fi wè.
Èyin ìjoba wa èbè la bèyín kí e má se jé kí òsèlú gba omolúàbí.

About Awoyemi Bamimore

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

Lati Ọwọ Aworosaṣa Moyọ Okediji

Cultural War Rages on: Africa’s Civilizations Are Being Erased—who Will Teach African Artists?

AFRICAN AESTHETICS Many universities in the West are developing core curriculum programs focused on “Western Civilization,” while increasingly purging African, African Diaspora, Asian, and other civilizations from their programs. The West focusing on Western Civilization is appropriate. The days of African and African Diaspora Studies seem numbered. At the same time, Africana artists are producing contemporary works like never before. What are these Africana artists going to read? Are they going to study Western Civilization only, without any understanding of ...