Home / Art / Àṣà Oòduà / Àwon agbésùmòmí Boko Haram pa àwon àgbè àti àwon ará ìlú ní Borno.
boko haramu

Àwon agbésùmòmí Boko Haram pa àwon àgbè àti àwon ará ìlú ní Borno.

Ókéré jù àwon ènìyàn méèdógún (15) ni a gbó pé àwon agbésùmòmí Boko Haram pa nígbà tí won kolu ara won. Ìròyìn tí Orísun àwon figilanté gbé ni wípé òpò àwon ará ìlú ní won sì ń wá léyìn Ìsèlè tí ó selè ní Jakete ní ìjoba ìbílè Konduga, agbègbè kan ní ìpínlè Borno. Ní kété agogo méwàá òwúrò àná ni won yín ìbon pa wón nínú oko won, tí a sì ń wá àwon obìnrin àgbè méfà.

Orísun àwon figilanté ti ìbílè náà jé kí ó di mímò wípé àwon àgbè náà gbìyànjú láti bó sùgbón agbára won kò ká àwon agbésùmòmí yìí…

Continue after the page break for English Version

About admin

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

“Ìyálóde, Eléékò & The Heavenly Companions: Discover the Mysterious Classes of Egbe in Yoruba Tradition”

Classes of Egbe (Heavenly Mate of Every Human) Also known as Alaragbo in some areas of Yoruba land, Egbe is generally more associated with children than with adults according to Eji-Ogbe. Based on the character traits of human on Earth, the Yoruba have classified Egbe into different categories. Ìyálóde Ìyálóde is regarded as the leader of Egbe on Earth. Leadership quality is most evident characteristic of this class of Egbe. Going by the name, it may appear that only females ...