Home / Art / Àṣà Oòduà / Ayé Kareem ti yí padà di òtun láti ìgbà tí ó ti ya àwòrán Ààre Macron- Alákoso rè ló so béè.

Ayé Kareem ti yí padà di òtun láti ìgbà tí ó ti ya àwòrán Ààre Macron- Alákoso rè ló so béè.

Óríre míràn ti to omo kékeré, omo odún mókànlá tí a mò sí Kareem Waris Olamilekan tí olórun fún ní èbùn kí ó ma ta nkan, ó ti ya ààre ilè Faransé tí a mò sí Ààre Emmanuel Macron, nígbà tí ó lo se àbèwò sí ojúbo Afrika tuntun ní ìlú Èkó.

Léyìn tí ó gba ilé ní owó Gómìnà ìpínlè Eko, ilé-ìfowópamó tí a mò sí Eko bank, ti towó bo ìwé láti gbà á tó lówó àwon òbí rè. Lára àwon èjé won ni wípé àwon yòó tó omo náà àti wípé àwon yóò ran lo sí ilé-èkó fún ogún odún(20 years).
Nínú ìfòrò wáni lénu wò tí won se fún alákoso Kareem tí a mò sí Adeniyi Adewole, ó jé kí ó di mímò wípé gbogbo ònà ni àwon n wá láti dábò bo ojó òla ayàwòrán omodé náà .
Ó so wípé inú òun dún púpò nítorí ilé-ìfówópamó ti Eco bank látàrí èjé tí won jé láti tójú omo náà. Ó so síwájú wípé sojú òun ni won se nígbá tí ó jé wípé òun ni Alákoso omo náà àti wípé won kò le se léyìn òun.

About Awoyemi Bamimore

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

“Ìyálóde, Eléékò & The Heavenly Companions: Discover the Mysterious Classes of Egbe in Yoruba Tradition”

Classes of Egbe (Heavenly Mate of Every Human) Also known as Alaragbo in some areas of Yoruba land, Egbe is generally more associated with children than with adults according to Eji-Ogbe. Based on the character traits of human on Earth, the Yoruba have classified Egbe into different categories. Ìyálóde Ìyálóde is regarded as the leader of Egbe on Earth. Leadership quality is most evident characteristic of this class of Egbe. Going by the name, it may appear that only females ...