Home / Art / Àṣà Oòduà / Bàbá Sàlá òrun rere re o. Gbajúgbajà elérí orí ìtàgé, tí gbogbo èèyàn mò sí bàbá Sàlá ti gba òrun lo ní àná ojó kesàn-án osù kèwà odún tí a wà yí.

Bàbá Sàlá òrun rere re o. Gbajúgbajà elérí orí ìtàgé, tí gbogbo èèyàn mò sí bàbá Sàlá ti gba òrun lo ní àná ojó kesàn-án osù kèwà odún tí a wà yí.


Tí won bá ni èèyàn apanilérìn ni baba won kò paró rárá, nítorí àwon gangan ni oyè adérìn-ín-p’òsónú ye.
Moses Olaiya Adejuwon (M.O.N), lórúko baba súgbón bàbá Sala ti gba orúko lówó won. Àsé kò sí eni tí kò ní kú, baba adérìn-ín-p’òsónú náà se bí eré lo sí òrun, Aláwàdà lo bá àwon baba rè lórun.
Baba Sala ó dìgbà, ó di ojú àlá.

About Awoyemi Bamimore

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

Iṣẹṣe Kọ́jọ́dá/calendar – Fún Oṣù Ẹ̀bìbí/May 2025.

TÍ OSU TITUN BÁ DÉ, ARÁYÉ MÁA Ń YỌ̀ MỌ́ NI, WỌN MÁA BÁ GBOGBO WA YỌ AYỌ̀ IRE NÍNÚ OSU TITUN YÍÌ, PẸ̀LÚ ÀṢẸ ELÉDÙMARÈ . 1. Ọbàtálá/Òrìṣà-ńlá, Ọbalúayé/Ṣàpọ̀nná, Ògìrìyàn, Egúngún, Ìyàmi Àjẹ́. 2. Ifá, Ọ̀rúnmìlà, Èṣù-Ọ̀dàrà, Orí, Odù, Ọ̀ṣun, Ajé-Olókun, Ọ̀sányìn, Kórì, Ẹgbẹ́. 3. Ògún, Ìja, Ọ̀ṣọ́ọ̀sì, Erinlẹ̀, Òrìṣà Oko. 4. Jàkùta/Ṣàngó, Ọya, Aganjú, Yemọja, Ìbejì, Nàná-Bùkúù. 5. Ọbàtálá/Òrìṣà-ńlá, Ọbalúayé/Ṣàpọ̀nná, Ògìrìyàn, Egúngún, Ìyàmi Àjẹ́. 6. Ifá, Ọ̀rúnmìlà, Èṣù-Ọ̀dàrà, Orí, Odù, Ọ̀ṣun, Ajé-Olókun, Ọ̀sányìn, Kórì, Ẹgbẹ́. 7. Ògún, Ìja, ...