Home / Art / Àṣà Oòduà / Ojó mánigbàgbé ní ilé-èkó gíga Obafemi Awolowo university (OAU).

Ojó mánigbàgbé ní ilé-èkó gíga Obafemi Awolowo university (OAU).

Ojó mánigbàgbé ní ilé-èkó gíga Obafemi Awolowo university (OAU).

Ìsèlè burúkú gbáà ní Óní selè ní ojó kewàá osù keje odún 1999 ní ilé-èkó gíga ifáfitì Obafemi Awolowo university nígbà tí èmi oní inú ire sì gba ibè lo.

Afrika se béè Ó ta èjè rè sílè fún àwon akékòó ilé-èkó yí láti dènà egbé òkùnkùn láti ìgbà náà ni àláfíà, ìfòkànbalè ti wà nínú ogbà yí. Njé ó wá ye kí á gbàgbé ojó yí bí?

Èní lópé odún mókàndínlógún tí Afrika kú fún wa, kí ló wá dé tí a kò le polongo “kí egbé òkùnkùn wá sí òpin ” kí lódé tí a kò le rántí èjè tí Óní kú fún akékòó?

Akoni ni Afrika ejé kí á se ayeye ìrántí fun, kí á kí àwon ebí rè wípé wón kú afárárekù eni rere..

Njé Ìwo tí setán láti gbógun ti egbé òkùnkùn bí?.

About Awoyemi Bamimore

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

Omisore

Àwàdà kẹrí-Kẹrì ni àwọn kọmití tó ní mi ò lè díje du ipò gómìnà APC ni 2026 n ṣe – Omisore

Yínká Àlàbí Awọn kọmiti to n ṣe àyẹ̀wò awọn oludije du ipo gomina labẹ ẹgbẹ́ oselu APC ti ja igbakeji gomina tẹlẹ ni ipinle Osun, Alagba Iyiola Omisore ati awọn mẹfa miiran.Wọn ni iwe wọn ko pe lati dije du ipo gomina ipinlẹ naa. Awọn mẹfẹẹfa to ku naa ni – Babatunde Oralusi, Oyedotun Babayemi, Dr. Akin Ogunbiyi, Benedict Alabi, Adegoke Rasheed Okiki, ati Senator Babajide Omoworare.Iyiola Omisore ni awada Kẹri-Kẹri ni awọn kọmiti naa n se nitori ti wọn ...