Home / Art / Àṣà Oòduà / Òkan lára Ilé ìgbé àwon akékòó ti Ilé-èkó gíga ifáfitì ti ìlú ilé-ifè tí a mò sí Obafemi Awolowo University gbiná lánàá.

Òkan lára Ilé ìgbé àwon akékòó ti Ilé-èkó gíga ifáfitì ti ìlú ilé-ifè tí a mò sí Obafemi Awolowo University gbiná lánàá.

Òkan lára ilé ìgbé àwon Akékòó ti ilé-èkó gíga ifafitì ti Obafemi Awolowo gbiná ní alé àná. Ilé ìgbé yìí a máa jé Alumni hostel, bí ó ti lè je wípé a kò fi tara tara mo bí ó se selè.
Gégé bí a se gbó, èrònjà tí a fi n dáná tí a mò sí gáàsì ti ó gbiná tí ó sì fa làásìgbò tí ó selè yí, ìròyìn jé kí á mò wípé yàrá bíi mérin ni ó gbinà látàrí àígboràn.
Won jé kí á mò wípé, gáàsì yí tí máa n rùn jáde télè kí ó tó di ojó náà, won sì ti máa n kìlò fún Akékòó tí ó ni gáàsì yí télè sùgbón tí ó kò láti gbó ìkìlò.
A tún ri gbó wípé, Yárá méta òtòtò ni ó gbiná sùgbón eni kankan kò kú níbè. Kí Elédúmarè máa fi ìsó rè só wa ooo.

About Awoyemi Bamimore

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

Omisore

Àwàdà kẹrí-Kẹrì ni àwọn kọmití tó ní mi ò lè díje du ipò gómìnà APC ni 2026 n ṣe – Omisore

Yínká Àlàbí Awọn kọmiti to n ṣe àyẹ̀wò awọn oludije du ipo gomina labẹ ẹgbẹ́ oselu APC ti ja igbakeji gomina tẹlẹ ni ipinle Osun, Alagba Iyiola Omisore ati awọn mẹfa miiran.Wọn ni iwe wọn ko pe lati dije du ipo gomina ipinlẹ naa. Awọn mẹfẹẹfa to ku naa ni – Babatunde Oralusi, Oyedotun Babayemi, Dr. Akin Ogunbiyi, Benedict Alabi, Adegoke Rasheed Okiki, ati Senator Babajide Omoworare.Iyiola Omisore ni awada Kẹri-Kẹri ni awọn kọmiti naa n se nitori ti wọn ...