Home / Art / Àṣà Oòduà / Bàbá Sàlá òrun rere re o. Gbajúgbajà elérí orí ìtàgé, tí gbogbo èèyàn mò sí bàbá Sàlá ti gba òrun lo ní àná ojó kesàn-án osù kèwà odún tí a wà yí.

Bàbá Sàlá òrun rere re o. Gbajúgbajà elérí orí ìtàgé, tí gbogbo èèyàn mò sí bàbá Sàlá ti gba òrun lo ní àná ojó kesàn-án osù kèwà odún tí a wà yí.


Tí won bá ni èèyàn apanilérìn ni baba won kò paró rárá, nítorí àwon gangan ni oyè adérìn-ín-p’òsónú ye.
Moses Olaiya Adejuwon (M.O.N), lórúko baba súgbón bàbá Sala ti gba orúko lówó won. Àsé kò sí eni tí kò ní kú, baba adérìn-ín-p’òsónú náà se bí eré lo sí òrun, Aláwàdà lo bá àwon baba rè lórun.
Baba Sala ó dìgbà, ó di ojú àlá.

About Awoyemi Bamimore

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

Happy New Calendar Year!!! It is 10068 of the Oodua Yoruba Calendar-–-KỌ́JỌ́DÁ

The Yoruba traditional calendar, called Kọ́jọ́dá, starts the new year on June 3rd and ends on June 2nd the following year. It’s a lunar calendar with a 4-day week (each day honoring different Orisa), 7 weeks in a month, and 13 months in a year—so their year is 364 days long. The months and weeks are deeply tied to farming cycles, moon phases, and religious rituals.The traditional Yoruba week has four days. The four days that are dedicated to the ...