Home / Art / Àṣà Oòduà / Bàbá Sàlá òrun rere re o. Gbajúgbajà elérí orí ìtàgé, tí gbogbo èèyàn mò sí bàbá Sàlá ti gba òrun lo ní àná ojó kesàn-án osù kèwà odún tí a wà yí.

Bàbá Sàlá òrun rere re o. Gbajúgbajà elérí orí ìtàgé, tí gbogbo èèyàn mò sí bàbá Sàlá ti gba òrun lo ní àná ojó kesàn-án osù kèwà odún tí a wà yí.


Tí won bá ni èèyàn apanilérìn ni baba won kò paró rárá, nítorí àwon gangan ni oyè adérìn-ín-p’òsónú ye.
Moses Olaiya Adejuwon (M.O.N), lórúko baba súgbón bàbá Sala ti gba orúko lówó won. Àsé kò sí eni tí kò ní kú, baba adérìn-ín-p’òsónú náà se bí eré lo sí òrun, Aláwàdà lo bá àwon baba rè lórun.
Baba Sala ó dìgbà, ó di ojú àlá.

About Awoyemi Bamimore

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

What is Àdìmù?

A few of my friends and students in the diaspora had asked me this question countless times, and I think it’s high time we discussed it.Please note that this is not an attempt to discredit or invalidate any practice or belief; this piece is just for us to educate one another.Now, in the Yoruba language, what does Adimu mean, or where does it originate from?Àdimu means “To hold.”The full word is Adimula, which means “to hold and prosper.”So, where does ...