Ẹ̀bùn Edùmarè ni ọmọ
Ẹ̀rí ìfẹ́ rẹ̀ sí wa ni wọ́n
Èdùmàrè à ń bẹ̀ ọ́
Bá wa wo àwọn èwe yè
Fi wọ́n fún àwọn tí ń wojú rẹ fún ẹ̀bùn wọn
Má ṣe jẹ́ kí wọ́n kú mọ́ àwọn òbí wọn lọ́wọ́
Èyí a wí yìí, kárọ̀ rọ̀ mọ́ ọn.
@AlamojaYoruba
Yínká Àlàbí Awọn kọmiti to n ṣe àyẹ̀wò awọn oludije du ipo gomina labẹ ẹgbẹ́ oselu APC ti ja igbakeji gomina tẹlẹ ni ipinle Osun, Alagba Iyiola Omisore ati awọn mẹfa miiran.Wọn ni iwe wọn ko pe lati dije du ipo gomina ipinlẹ naa. Awọn mẹfẹẹfa to ku naa ni – Babatunde Oralusi, Oyedotun Babayemi, Dr. Akin Ogunbiyi, Benedict Alabi, Adegoke Rasheed Okiki, ati Senator Babajide Omoworare.Iyiola Omisore ni awada Kẹri-Kẹri ni awọn kọmiti naa n se nitori ti wọn ...