Home / Art / Àṣà Oòduà / Òrìsà tí ń darí aféfé

Òrìsà tí ń darí aféfé

Oya òpèré,
Ekùn oko asè’ké
Oya má bá mi jà
Mi ò l’ówó aféfé ńlé

Èmi ò rí eni tí yó ràgàn, ràgàn bí Oya ní òde ìpo
Kò séni tí ó ràgàn ràgàn bí Oya lótù ifé

Oya lo ràgàn ràgàn
Ló re nú ìgbé lò ké sí
Omo oyá d’olú
Oya mòdè ooo

Òpèré ní won ń jé
Òpéré ni won jé ó e
Gbogbo ilé olóya
Òpérè ni won je o e

Oya ní ìyá òun ò l’órogún
Óní òun náà ko ní l’óba kan
Òrìsà mérìndínlógún ni Oya bá n’ílé Sàngo gbogbo won ló fi eyin ojú lé lo. .

About Awoyemi Bamimore

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

Onibode

The Tale of Oníbodè Lálúpọn and the Dundun Drummer

Long ago, in the ancient city of Ibadan, famed for its warriors and sprawling hills, there lived a gatekeeper-warrior stationed in the outskirts of the city, in a settlement known as Lálúpọn on the way to Ìwó. His duty was clear: to watch the road, collect tolls, and guard the passage of traders and travellers entering and leaving Ibadan. Because of this important task, people called him Oníbodè Lálúpọn; the Gatekeeper of Lálúpọn. Though he was not particularly comely, Oníbodè ...