Home / Art / Àṣà Oòduà / Òrìsà tí ń darí aféfé

Òrìsà tí ń darí aféfé

Oya òpèré,
Ekùn oko asè’ké
Oya má bá mi jà
Mi ò l’ówó aféfé ńlé

Èmi ò rí eni tí yó ràgàn, ràgàn bí Oya ní òde ìpo
Kò séni tí ó ràgàn ràgàn bí Oya lótù ifé

Oya lo ràgàn ràgàn
Ló re nú ìgbé lò ké sí
Omo oyá d’olú
Oya mòdè ooo

Òpèré ní won ń jé
Òpéré ni won jé ó e
Gbogbo ilé olóya
Òpérè ni won je o e

Oya ní ìyá òun ò l’órogún
Óní òun náà ko ní l’óba kan
Òrìsà mérìndínlógún ni Oya bá n’ílé Sàngo gbogbo won ló fi eyin ojú lé lo. .

About Awoyemi Bamimore

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

Omisore

Àwàdà kẹrí-Kẹrì ni àwọn kọmití tó ní mi ò lè díje du ipò gómìnà APC ni 2026 n ṣe – Omisore

Yínká Àlàbí Awọn kọmiti to n ṣe àyẹ̀wò awọn oludije du ipo gomina labẹ ẹgbẹ́ oselu APC ti ja igbakeji gomina tẹlẹ ni ipinle Osun, Alagba Iyiola Omisore ati awọn mẹfa miiran.Wọn ni iwe wọn ko pe lati dije du ipo gomina ipinlẹ naa. Awọn mẹfẹẹfa to ku naa ni – Babatunde Oralusi, Oyedotun Babayemi, Dr. Akin Ogunbiyi, Benedict Alabi, Adegoke Rasheed Okiki, ati Senator Babajide Omoworare.Iyiola Omisore ni awada Kẹri-Kẹri ni awọn kọmiti naa n se nitori ti wọn ...