Home / Art / Àṣà Oòduà / Timi Dakolo pín àwòrán ti ó rewà ti ìyàwó rè pèlú omo méta ní London.

Timi Dakolo pín àwòrán ti ó rewà ti ìyàwó rè pèlú omo méta ní London.

Gbajúgbajà olórin ti orílè èdè Nìjíríà, Timi Dakolo ti pín àwòrán ìyàwó rè àti àwon omo rè méta ní ìlú London, ó ko síbè wípé “wón tun ti dé baba wón tún ti dé”.

Timi Dakolo ti ó jé omo bíbí ìlú Accra ní orílè èdè Ghana tí baba rè sì jé omo Bayelsa ìlú kan ní orílè èdè Nìjíríà, orúko rè a máa jé David tí ìyá rè sí jé omo bíbí orílè èdè Ghana, orúko òun náà a máa jé Norah, tí ó kú nígbà tí Timi wà ní omo odún métàlá(13).

Bí ó tilè jé wípé omo bíbí orílè èdè Ghana ni Timi jé, tí ó sì tún ní ìwé omo ìlú ti orílè èdè Nìjíríà lówó, kò f’ìgbà kan so rí wípé omo ìlú méjì ni òun .

Njé èyí kò rewà bí?

About Awoyemi Bamimore

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

policeman

Ọ̀gbẹ́ni Olaoye déèdé pòórá nílé ìtura kan nílùú Akure

Fẹ́mi Akínṣọlá Ádùrá tí a máa ń ṣe ni pé kí á má rin àrin f’ẹsẹ̀sí.Mọ̀lẹ́bí ọkùnrin kan, Ògbẹ́ni Olaoye Olatunde, tó jẹ́ igbákejì ọ̀gá àgbà ilé ẹ̀kọ́ girama kan nílùú Ọwọ ti ké gbàjarè pé ọkùnrin náà di àwárítì lẹ́yìn tó lọ fún idanilẹkọ ní ilé ìtura Sunview nílùú Akure. Iyawo arakunrin naa salaye rẹ pe, ni ọjọ kẹrinlelogun oṣu Kẹjọ, ọdun 2025, ni ọkọ rẹ dagbere pe ohun n lọ fun idanilekọ kan n’iluu Akure, eyi ti wọn ...