Home / Art / Àṣà Oòduà / Òdómobìnrin tí ó gba òrékùnrin tè s’ílé nítorí wípé kò ní isé l’ówó bá pátá àti róbà ìdábòbò nínú ilé rè.

Òdómobìnrin tí ó gba òrékùnrin tè s’ílé nítorí wípé kò ní isé l’ówó bá pátá àti róbà ìdábòbò nínú ilé rè.

     Gégé bí ìtàn se so è yun-ùn tí won pín sí orí èro ayélujára (IG) ti Joro Olumofin. Òdómobìnrin tí ó gba òrékùnrin rè tí kò n’ísé l’ówó gbé nínú ilé rè ní Eko padà délé láti ìrìn-àjò tí ó lo láti ya òrékùnrin rè lénu sùgbón tí ó padà ri wípé n se ni omokùnrin náà n re je.

Gégé bí ó se so, òrékùnrin náà n fi tipátipà jé kí ó fi pátá tí ó won ìwòn mérìnlá (14) sílè fún oní ìwòn méwàá(10) sùgnón ìyàlénu lójé wípé obìnrin náà rí pátá tí ó won ìwòn méjìdínlógún nínú balùwè…

About Awoyemi Bamimore

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

Onibode

The Tale of Oníbodè Lálúpọn and the Dundun Drummer

Long ago, in the ancient city of Ibadan, famed for its warriors and sprawling hills, there lived a gatekeeper-warrior stationed in the outskirts of the city, in a settlement known as Lálúpọn on the way to Ìwó. His duty was clear: to watch the road, collect tolls, and guard the passage of traders and travellers entering and leaving Ibadan. Because of this important task, people called him Oníbodè Lálúpọn; the Gatekeeper of Lálúpọn. Though he was not particularly comely, Oníbodè ...