Home / Art / Àṣà Oòduà / Igbeyawo Asofin Moji Lawal niluu Eko leku!

Igbeyawo Asofin Moji Lawal niluu Eko leku!

Arabirin Moji Lawal, okan ninu awon omo ile igbimo asofin ipinle Eko segbeyawo alarinrin lopin ose to koja yii pelu oko re, John Paul to je onisowo pataki.

Arabirin Moji, eni to je obirin akoko ti o ma soju ekun Apapa nile igbimo asofin ipinle Eko naa lo je omidan kan soso laaarin awon asofinbirin saaju ko to so yigi pelu oko re lose to koja yii.

Arabirin Moji, eni to ti figba kan sise pelu gomina Ipinle Eko nigba kan ri, Bola Tinubu, gege bi oludamoran fun awon iroyin to ni i se pelu imo ero, lo lodije ninu eto idibo abele egbe APC pelu awon oludije bi ogorun ko to di wi pe o jawe olubori lati kopa ninu eto idibo gbogboogbo.

Ninu eto idibo gbogboogbo naa lo tun ti pegede lati je okan lara awon omo ile igbimo asofin Ipinle naa.

Eto igbeyawo ti won se ni ilana esin musulumi naa la gbo wi pe o waye leyin ti toko-toya naa ti lo si kootu lati lo so yigi won labe ofin.

Oniroyin: Olayemi Olatilewa

Send Money To Nigeria Free

About admin

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

The Èkó(s) of the Oòduà (Yorùbá) Homeland.

Èkó-Ènde (Ìfẹ́lódùn LGA, State of Ọ̀ṣun)Èkó-Àkéte (Lagos Island LGA, Lagos State)Èkó-Àjàlá (Ìfẹ́lódùn LGA, State of Ọ̀ṣun)Èkó – Efun ( Amongst The Olukumi of Delta state) 2021 Edition of the Ọ̀tín-Èkó Festival where the Ọ̀tín River is celebrated by the Èkó people around the River in Ọ̀ṣun. Ọtín River is a very important one in Yorùbá history. It was the river that drowned the highest number of terrible invaders of the Homeland in the Jálumi war of November 1, 1878.In fact, ...