Home / Art / Àṣà Oòduà / Kílódé tí àwon omoge fi n’ìfé àwon tí ó ti n’íyàwó.

Kílódé tí àwon omoge fi n’ìfé àwon tí ó ti n’íyàwó.

E jòwó mo fé kí e dá mi lóhùn dáadáa.

Gbogbo àwon Òré mi tí ó ti n’íyàwó n’ílé ni òpò obìnrin ń súré tè lé, tí ó sì jé wípé àwon àpón bí ti àwa yí obìnrin díè ni ó súré tèle wa, mo ti è fé mò gan. Àti àwon( Òré mi tí ó ti n’íyàwó) jé éri si èyí, wípé àwon omoge ń du àwon tí ó ti n’íyàwó, wón gbàgbó wípé àwon máa ń se ìtójú obìnrin dáadáa, e jòwó Sé òtító ni èyí?

Obìnrin  Lásán…

About Awoyemi Bamimore

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

“Ìyálóde, Eléékò & The Heavenly Companions: Discover the Mysterious Classes of Egbe in Yoruba Tradition”

Classes of Egbe (Heavenly Mate of Every Human) Also known as Alaragbo in some areas of Yoruba land, Egbe is generally more associated with children than with adults according to Eji-Ogbe. Based on the character traits of human on Earth, the Yoruba have classified Egbe into different categories. Ìyálóde Ìyálóde is regarded as the leader of Egbe on Earth. Leadership quality is most evident characteristic of this class of Egbe. Going by the name, it may appear that only females ...