Home / Author Archives: ayangalu (page 33)

Author Archives: ayangalu

efcc

Orisirisi: Àwọn àǹjàǹnú ń gbowó oṣù l’ájọ Sùbẹ́ẹ̀bù Kwara- EFCC

Àwọn àǹjàǹnú ń gbowó oṣù l’ájọ Sùbẹ́ẹ̀bù Kwara- EFCC Àjọ tó ń gbógun ti ìwà jẹgúdújẹrá lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà EFCC sọ pé àṣírí àwọn ayédèrú òṣìṣẹ́ ẹgbẹ̀rún kan àjọ tó ń ṣàkóso ètò ẹ̀kọ́ alákọ̀ọ́bẹ̀rẹ̀ nípìńlẹ̀ Kwara ti tú sí àwọn ...

Read More »
corona

Èèyàn 627 ló lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Naijiria ní Ọjọ́ Ẹtì

Èèyàn 627 ló lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Naijiria ní Ọjọ́ Ẹtì Ẹgbẹ̀ta lé lọ́gbọ̀n o dín mẹta èèyàn (627 )tuntun míì ló ṣẹ̀sẹ̀ lùgbàdi àrùn Kofi -19 ní Nàìjíríà. Àjọ tó ń rí sí ìdènà àti amójútó àjàkálẹ̀ àrùn apinni ...

Read More »

Olu Jacobs sì wà láàyè

Olu Jacobs sì wà láàyè Agba oje ninu ere ori itage ni ede Oyinbo, Alagba Olu Jacobs ni awon iroyin eleje kan n gbee kiri lori ero ayelujara lati aaro oni pe, “olodi baba naa ti lo je ipe awon ...

Read More »
policeman

O̩wó̩ pálábá 185 nínú o̩mo̩ e̩gbé̩ òkùnkùn ségí l’Eko

O̩wó̩ pálábá 185 nínú o̩mo̩ e̩gbé̩ òkùnkùn ségí l’EkoYínká Àlàbí Komisona olopaa ni ipinle Eko, Ogbeni Hakeem Odumosu tenu moo ipinle Eko ko ni faaye gba egbe okunkun rara. Eyi lo faa to fi tete pakiti mole lati gbogun ti ...

Read More »
rape

Ìdájọ́ ikú kò pọ̀jù fún gbogbo afipá bánilòpọ̀ – Ẹgbẹ́ ajàfẹ́tọ̀ọ́ ọmọnìyàn

Ìdájọ́ ikú kò pọ̀jù fún gbogbo afipá bánilòpọ̀ – Ẹgbẹ́ ajàfẹ́tọ̀ọ́ ọmọnìyàn Àgbáríjọpọ̀ àwọn ẹgbẹ́ ajàfẹ́tọmọnìyàn bíi mẹ́rìnlà ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ ti korò ojú sí ìwà ìfipábánilòpọ̀ àti ìṣekúpani tí àwọn obìnrin ń kojú láwùjọ. Nínú ìpàdé àwọn oníròyìn tó wáyé lópin ...

Read More »
corona

Gómìnà ìpínlẹ̀ Abia, Okezie Ikpeazu ti fara kásá àrùn Covid-19

Gómìnà ìpínlẹ̀ Abia, Okezie Ikpeazu ti fara kásá àrùn Covid-19 Bí àwọn èèyàn kan ṣe rò pé eré orí ìtàgé ni ariwo t’íjọba ń pa lórí àjàkálẹ̀ àrùn apinni léèmí Kòrónáfairọ̀ọ̀sì yìí, bẹ́ẹ̀ ni Ìjọba lẹ́lẹ́kaǹka náà n ké tòòò ...

Read More »
waec

Kété tí wọ́n bá ṣí iléẹ̀kọ́ padà ní ìdánwò WASSCE yóò bẹ̀rẹ̀…Àjọ WAEC

Kété tí wọ́n bá ṣí iléẹ̀kọ́ padà ní ìdánwò WASSCE yóò bẹ̀rẹ̀…Àjọ WAEC Ìgbà lonígbà ń kà, àkókò ò wojú ẹnikẹ́ni àyàfi èèyàn tó bá setán àti ṣàmúló rẹ̀ lójú ọjọ́.Bí a bá wo ọṣẹ́ tí àrùn apinni léèmí Kòrónáfairọ̀ọ̀sì ...

Read More »
catholic church

Àwo̩n S̩ó̩ò̩sì bè̩rè̩ ìjó̩sìn l’Abuja lónìí

Àwo̩n S̩ó̩ò̩sì bè̩rè̩ ìjó̩sì l’Abuja lónìíYínká Àlàbí O le ni osu meji bayii ti ijoba apapo ti fofin de Soosi ati Mosalasi. Ijoba ni ki onikaluku maa josin ni ile won, ijoba ni ko si ibi ti Olorun ko si ...

Read More »

Odún dé, Gbogbo Irúnmolè e gbé ire wá

Our World Ifa festival has come, all divinities, we request that goodness is brought to us all. Just listen to Òsé Orógbe as follows:- Eésan ò sé gbá lójúÀkeèkèé ò se é dìníbòAdífá fún Odún tíí se Yèyé ObaÒsé tééré ...

Read More »
kojoda_10062

KỌ́JỌ́DÁ 10062: Odún Dé Omo Eríwo…

Happy world Ifa Festival to all the traditionalist around the globe.Irinwó imolè, igba imolè, Olódùmarè yóò gba gbogbo irè wa, àmódùn á jù báyìí lo. We shall all witness more of it on earth. Ajoke Olóbì❣️❣️❣️❣️❣️ Kojoda 10,062

Read More »

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb