Home / Art / Àṣà Oòduà / È̩yin òsìsé̩ mi nílò àyè̩wò coronavirus kíákíá- Akeredolu
Akeredolu

È̩yin òsìsé̩ mi nílò àyè̩wò coronavirus kíákíá- Akeredolu

È̩yin òsìsé̩ mi nílò àyè̩wò coronavirus kíákíá – Akeredolu

Arakunrin Rotimi Akeredolu ti o je gomina ipinle Ondo lo n gba awon alabasise re niyanju ki won fi oro ti oun se arikogbon.


O ni iba lasan ni o se oun ti oun si se itoju ara laarin ojo meji pere. O ni leyin re ni awon ore gba oun nimoran lati se ayewo ajakale arun coronavirus.


Gomina naa ni “iyan jija lo n ba ore je” oun se ayewo ti esi ayewo si gbe pe oun ti ko arun naa.


O ni tii di asiko yii, oun ko tii le so ibi ti ati ona ti oun gba ko aisan naa. Alagba Akeredolu salaye yii funra re lori afefe pe ki won wo oun pe saka ni ara da.

Oun ko tile ni inira kankan ni eyi ti awon onimo oyinbo ni ohun lo dara ju. Won ni ti eniyan ba tete kefin arun yii ti o si tete gbogun tii lo dara ju ki o to wo ara.


Eyi lo mu ki gomina gba awon osise re niyanju pe ki won tete lo se ayewo ara won nipa arun naa ki eni to ba nii le tete gbogun tii.

Yínká Àlàbí

About ayangalu

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

History 101: What it takes to be a MENTALLY ENSLAVED FOOL in Your ancestral Land.

History 101: What it takes to be a MENTALLY ENSLAVED Harlequin in Your ancestral Land.

The quote for today is a page from Toyin Falola’s book, ‘Yoruba Warlords of the 19th Century’. To a lot of Yoruba Muslims. Islam means servitude to Usman Dan Fodio’s estate at Sokoto. They indulge in the same idiocy that led to the fall of the great Hausa civilization. Many Yoruba Muslims from Oyo are a dangerously brainwashed set of people that would pose future danger for the preservation of Yorubaland like their ancestors who pledged allegiance to Ilorin and ...