Home / Art / Àṣà Oòduà / Abiola Ajimobi sùn un re
abiola ajimobi

Abiola Ajimobi sùn un re

Ikú pàgbẹ̀ àṣírí aláró tú.
Ikú pàlùkò àbùkù kará ìkosùn.
Ọrùn má kánjú, gbogbo wa la dágbádá ikú.
Ìgbà átàsìkò ẹ̀dá ló só kùnkùn.
Gíńgín ladáhunṣe tó mewé e re.
Gbogbo wa lòpè nípa àkúnlẹ̀yàn.
Òkú ń sunkú òkú, akáṣọlérí ń sunkú ara a wọn.
Sùn un re oo Àjànàkú ọkọ Florence, Àkànjí ẹ̀rù , mọ́ ṣẹ̀rù baya, bọmọ tó o fi sáyé lọ.
Má ṣẹ̀rù bàlú, sun- un-run ìgbẹ̀yìn pàdé Allah nídẹ̀ra .

Àkànjí ẹ̀rù Sheeeeuuu,ibi o fàdàgbá ayé rọ̀ sí, ọmọ ni yóó lòyókú.

About ayangalu

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

History 101: What it takes to be a MENTALLY ENSLAVED FOOL in Your ancestral Land.

History 101: What it takes to be a MENTALLY ENSLAVED Harlequin in Your ancestral Land.

The quote for today is a page from Toyin Falola’s book, ‘Yoruba Warlords of the 19th Century’. To a lot of Yoruba Muslims. Islam means servitude to Usman Dan Fodio’s estate at Sokoto. They indulge in the same idiocy that led to the fall of the great Hausa civilization. Many Yoruba Muslims from Oyo are a dangerously brainwashed set of people that would pose future danger for the preservation of Yorubaland like their ancestors who pledged allegiance to Ilorin and ...