Home / Art (page 147)

Art

asa yoruba

Tani Obalufon Ati Kini Ojuse Re?

Ekaaro eyin eniyan mi, aojiire bi? Aku ise ana o, a si tun ku imura toni eledumare ninu aanu re koni jeki a we ninu agbara eje bi a se njade lo loni o ase. Laaro yi mo fe se ...

Read More »
naija gist

Posita gbigba okore pada Kun ilu Port-Harcourt Egba ni eleja

Posita wagba okore kun igboro ilu Port-Harcourt    

Read More »
naija gist emoney

Eyin eniyan e wo E-moni(E-money) ninu photo titun re.

Alaga ti Ẹgbẹ eka marun apapo , wuni ninu poto re titun ti o sese ya.

Read More »
tonto

Tonto Dikeh ki Mercy Johnson pe ‘oku orire fun ipo titun ti Gomina Kogi sese yan si’.

Awuyewuye ija ti oun lo laarin awọn oṣere Tonto Dikeh ati Mercy Johnson, Tonto Dikeh ti toro aforiji lori awọn gbólóhùn o ṣe nipa ọmọ rẹ ati awon oro miran to ti so ni odun die seyin. Mercy Johnson gba ebe ...

Read More »
asa-yoruba

Aseritu: Awon Agbofinro ‘SON’ Ri Ile Alaja Meji Ti Won Ko Ogun Ti O Ti Ba Je Si. (Aworan)

Awon  ‘SON’ (Standards Organisation of Nigeria) ti mu ogbeni akeruwole ti oun ta aye deru Kosimetik ati ọti-waini ti se ayipada awọn ogun ti ọjọ ti lo lori wọn ati ti o nri titun ọjọ lori wọn, ni eyi ti ...

Read More »
lion

Ẹ̀rù ló sọ ọmọ Ẹkùn di Ológbò/Ológìní tó fi di ” Ẹran-àmúsìn – Ọdẹ peku-peku” –

Ni igbà àtijọ́, ẹranko ti wọn pè ni Ẹkùn jẹ alágbára ẹranko, bẹni Kìnìún si jẹ́ alágbára ẹranko. Bi Kìnìún ti lágbára tó ninú igbó, bi ó bá bú ramúramù, ohun gbogbo ninú igbó á pa kẹ́kẹ́ titi dé ori ...

Read More »
Cocoa farmer

“Àṣejù Baba Àṣetẹ́” – Ìtàn bi Ojúkòkòrò àti Ìgbéraga ti jẹ́ Àṣejù

Ni ìgbà àtijọ́, ọkùnrin kan wa ti orúkọ rẹ njẹ́ Ìgbéraga. Wọ́n bi Ìgbéraga si ilé olórogún, àwọn ìyàwó bàbá́ rẹ yoku ni ó tọ nitori ìyá rẹ kú nigbati ó wà ni kékeré. Lẹhin ti o tiraka lati pari ...

Read More »
beeni

Omo Yo’ooba: Se Looto Ni?

Se beeni abi be ko ?

Read More »
elenini

Who is Elenini ?

Following my last post on “who is Elenini”, here is my own submission.  My senior sister, Olayinka Moussa described Elenini as antagonist. The President of International Council for Ifa Religion, Oloye(Prof). Idowu Odeyemi said, “not all critics are enemies, not ...

Read More »
nasarawa state

Photo of the day !

Traditional festival in northern part of Nigeria, Nassarawa state, Nigeria!!! Is this not African spirituality??? I love this!!!

Read More »

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb