Kí gbogbo àwọn olórí ààbò lọọ rọ́kún nílé – Ilé ìgbìmọ̀ asojúLáti ọwọ́ Yínká Àlàbí Abajade ipade ile igbimo asoju to wa ni Abuja ni “a kuku joye san ju enu mi ko ka ilu lo”. Won ni ki gbogbo ...
Read More »Jonathan sàbẹ̀wò sí Buhari
Ara iroyin yajoyajo to wole ni abewo ti Aare ana, Omowe Goodluck Jonathan se si Aare Mohammadu Buhari ni Aso Villa to wa ni oluulu Naijiria ni Abuja. Ipade bonkele ni ipade yii nitori pe awon mejeeji tilekun mori ni, ...
Read More »Ìdíle Saraki àti ìjọba ìpínlẹ̀ Kwara dájọ́ ìpàdé
Lẹ́yìn tí Ìjọba Ìpínlẹ̀ Kwara ti tẹ̀lé òfin tí wọ́n wo ohun ìní ìdílé Saraki èyí tí wọ́n ń pé ibẹ̀ ni Ilé Arúgbó ní ìlú Ilorin, ìpínlẹ̀ Kwara, gbogbo àwọn tọ́rọ̀ kan nínú rẹ̀ ti wá gbà láti yanjú aáwọ̀ láì ti ọwọ́ Ilé ẹjọ́ bọ̀ ọ́ mọ́.
Read More »Àse Ifá
Àse Ifá ( supplication) from Ejiogbe at our Temple, Indigene Faith of Africa(Ijo Orunmila Ato) Inc today, Ose Ifa, 25th January 2020 titled Èyónú Àwon Ìyà mi Àjé lósunwònÌbínú won kò dára Affection of Our Powerful Spiritual Mothers ( Great ...
Read More »The Importance Of Ori In Our Lives
Ori is our inner spiritual connection and the veneration of the naturalism of a spirituality . In all spirituality , ori is the connective bond between us and Olodumare. Everyone has Ori irrespective of your religion and spirituality . Ori is ...
Read More »Àwọn Yèyélórìṣà, Akirè Shrine Ilé Ifẹ̀, 2003.
Pitcture was taken by Prof. Moyo Okediji in 2003, he returned to find the group in 2015. But for the two women at the extreme left, all the others had transitioned.
Read More »Ò̩pò̩ dúkìá sègbé sínú ìjàm̀bá iná ló̩jà Amu l’Ekoo
Ò̩pò̩ dúkìá sègbé sínú ìjàm̀bá iná ló̩jà Amu l’EkooLáti o̩wó̩ Yínká ÀlàbíEledua jowo maa so wa pelu ijamba ina to n sele lasiko eerun yii.Lojiji ni ijamba tun be yo ni oja gbaju-gbaja Amu ti o wa ni ilu Mushin ...
Read More »Amotekun: Read Mr Akeredolu’s Remarks After The Meeting On Thursday
Well we had a very fruitful discussion. Governors of south west as you know we were all there.
Read More »‘Oko Oloyun’, Traditional Medical Expert, Shot Dead
Fatai Yusuf, alternative medicine practitioner better known as “Oko Oloyun”, is dead. He was reportedly shot dead on the Eruwa-Igboora road in the Ibarapa Central area of Oyo state on Thursday. Details of the death of Yusuf are still sketchy ...
Read More »Ilé-ẹjọ́ Tó Ga Jù Ní Samuel Ortom Náà Ló Tún Jáwé Olúborí Ní Benue
Ilé-ẹjọ́ tó ga jù ní Samuel Ortom náà ló tún jáwé olúborí ní BenueLáti ọwọ Yínká Àlàbí Iroyin yajoyajo to wole bayii lo n jeri sii bi ile ejo to ga ju lo to fi ikale si ilu Abuja se ...
Read More »