Home / Art / Àṣà Oòduà / Èmi kò ní àrùn coronavirus – Yahaya Bello
Yahaya Bello

Èmi kò ní àrùn coronavirus – Yahaya Bello

Gomina ipinle Kogi,Ogbeni Yahaya Bollo lo n forere lori ero ayelujara pe ki won se fi orokoro ko oun lorun, oun lo ni arun covid-19 gege bi awon oloselu Kan se n gbee kiri.


O ni loooto ni adari aabo ijoba apapo, Alagba Abba kyari to ni arun naa ba oun lalejo nigba ti o ti orileede Germany de.

O ni o wa ba oun kedun iku mama oun. O ni abewo naa ko muu dandan pe oun gbodo ko arun naa. O ni oun nikan ko ni ko ko arun naa lara re, Alhaji Lai Mohammed naa wa lara awon to fi abewo ye ohun si pelu awon eniyan pataki miiran.


Gomina tun wa ro awon oloselu ti won ko mo ju ki won ko owo je lo,o ni ko dara ki won fi arun coronavirus ko owo je rara. O ni asiko to ye ki iberu Olorun wa ju niyi. O ni oun ko si ni gba ki oloselu kankan lo oun lati ko owo je, eyi lo mu ki oun maa forere pe oun ko ni arun coronavirus rara.

About ayangalu

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

History 101: What it takes to be a MENTALLY ENSLAVED FOOL in Your ancestral Land.

History 101: What it takes to be a MENTALLY ENSLAVED Harlequin in Your ancestral Land.

The quote for today is a page from Toyin Falola’s book, ‘Yoruba Warlords of the 19th Century’. To a lot of Yoruba Muslims. Islam means servitude to Usman Dan Fodio’s estate at Sokoto. They indulge in the same idiocy that led to the fall of the great Hausa civilization. Many Yoruba Muslims from Oyo are a dangerously brainwashed set of people that would pose future danger for the preservation of Yorubaland like their ancestors who pledged allegiance to Ilorin and ...