Home / Art (page 78)

Art

Ifa: Oroororo is the babalawo of Oloro

By Oloye Abifarin A friend came to me who is also a young babalawo, he said he’s new on cast of Ifá for people in diaspora. He told me that he cast Ifá for one of his friend who’s an African ...

Read More »
Agganyu orisa

Facts about Orisha Agganyu

Written by Oluwo Fayemiwo Olokun‎ Agganyu also spelled Aganyu, Agganju, Argayú or Agayu Sola) is the orisha of volcanos. He is also the ferryman that helps people cross the river, and some lineages say Aggayú is the orisha of deserts. There ...

Read More »

Ìpínlè Osun, Ìpínlè Omolúàbí yóò yan ìpín won lónìí, ojó Àbáméta nígbà tí won yóò dìbò fún eni tí won fé gégé bí gómìnà Omolúàbí.

Gégé bí a ti mò wípé òní tí ó jé Ojó Àbáméta ni ìpínlè Osun yóò dìbó fún ènìyàn tí won fé kí ó di aláse lórí won. Egbé kòòkan sì ti fi omo egbé sílè . Gboyega Oyetola ni ...

Read More »

Gómìnà Arégbésolá fún àwon olùkó ní èbùn okò àti àwon èbùn míràn.

Gómìnà ìpínlè Osun tí a mò sí Rauf Aregbesola lo sí àjo àwon ilé-èkó àwon alákóbèrè pèlú àwon adarí míràn tí won péjú sìbè láti pín okò fún àwon òsìsé. Kìí se okò níkan ni ó fún won o bí ...

Read More »

Àwon arákúnrin méjì kan jà lórí eni tí yóò jókòó sí iwájú okò.

Àwon èrò méjì ni a rí lónìí tí won n jà látàrí eni tí yóò jóko sí iwájú oko ní Èkó . Nígbà tí ó yá ni awakò ti awon méjèèjì jábó látàrí bí won se n se bí eni ...

Read More »

Arákùnrin kan ni ó kú sínú odò nígbà tí ó sòrò nípa èmí òkúnkún.

Arákùnrin tí ó n gbé ní Èkó ni ó kú nígbà tí ó lo kí ègbón rè ní Ujeme, Ekpoma, ìpínlè Edo, ní won ti rí òkú rè nínú odò ní ilé rè, léyìn tí a gbó wípé ó sonù. ...

Read More »

Linda Ikeji padà so orúko baba omo rè, ó wípé Sholaye Jeremi ni baba omo òun àti oko tí n bò lónà.

Elétí Ofe, Linda Ikeji ti padà so baba omo rè, ó sì ti so wípé Sholaye Jeremi ni baba omo òun . Ó tún so wípé orúko omo òun ni Jayce Jeremi , ó ko síbè wípé… ” mò n ...

Read More »

Davido, Gbajúgbajà olórin tí ó tún jé omo ebí Adeleke wo agbádá tí àwon egbé oní Àsìá se tí won sì ko orúko egbé won si.

Olórin, tí ó tún jé òtòkùlú ti n se isé takuntakun láti ri dájú wípé, sínétò Ademola Adeleke di Gómìnà ìpínlè Òsun ní ibi ìdìbò tí ó n bò ní ojó àbáméta yí. Ó tí è ti n sisé takuntakun ...

Read More »

Akékòó tí ó se dáradára jùlo ní ilé-èkó gíga tí a mò sí ABUAD gba èbùn nlá fúm oríre yí.

Bí omo eni bá dára kí á wí, Akékòó gboyè ti ìmò tí ó n se ìtòjú ènìyàn tí a mò sí Medical Student, ti gba èbùn pàtàkí tí a mò dí Okò bògìnì àti owó goboi. Esther Azom ni ...

Read More »

Gbajúgbajà elétíofe, tí a mò sí Linda Ikeji ti bí omo okùnrin làntì lanti

Gbajúgbajà a gbé òrò sórí aféfé ti gbe sí orí èro ayélujára tí a mò sí insitagiramu, láti jé kí gbogbo àgbáyé mò wípé òun ti bímo, nígbà tí ô ya àwòrán n’ílé ìwòsàn, tí ó sì pe omo máà ...

Read More »

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb