Home / Art / Àṣà Oòduà / A kú àmójúbà Osù Eréna (March) tuntun.

A kú àmójúbà Osù Eréna (March) tuntun.

Osù ìdèra, ìtèsíwájú, ìse rere ni yóò jé fún gbogbo wa. Nínú Osù tuntun yìí, àìsàn kò níí jé ìpín enìkóòkan wa. Eni yòówù tí àìlera bá n dà láàmú, Olódùmarè yóò so ó dèrò. A kò níí rí ìjà ìgbóná. Bí ó tilè wù kí ilé ó gbóná tó, Oba Adédàá yóò so ó dèrò. Àìsàn tí n gba oúnje lénu eni kò níí se wa, èyí tí n gba apá, esè, àti gbogbo èyà ara lówó eni kò níí jé ìpín wa nínú Osù yii. Àjíñde ara yó máa jé o.

Ilé tútù
Ònà tútù
A dí fá fún Olúweri-Mògétì
Àtòjò
Àtèrún
Ilé Olúweri kì í gbóná…

Ilé àti ònà kò níí gbóná mó wa nínú Osù yìí..

Send Money To Nigeria Free

About Awoyemi Bamimore

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

The Èkó(s) of the Oòduà (Yorùbá) Homeland.

Èkó-Ènde (Ìfẹ́lódùn LGA, State of Ọ̀ṣun)Èkó-Àkéte (Lagos Island LGA, Lagos State)Èkó-Àjàlá (Ìfẹ́lódùn LGA, State of Ọ̀ṣun)Èkó – Efun ( Amongst The Olukumi of Delta state) 2021 Edition of the Ọ̀tín-Èkó Festival where the Ọ̀tín River is celebrated by the Èkó people around the River in Ọ̀ṣun. Ọtín River is a very important one in Yorùbá history. It was the river that drowned the highest number of terrible invaders of the Homeland in the Jálumi war of November 1, 1878.In fact, ...