Home / Art / Àṣà Oòduà / A kú àmójúbà Osù Eréna (March) tuntun.

A kú àmójúbà Osù Eréna (March) tuntun.

Osù ìdèra, ìtèsíwájú, ìse rere ni yóò jé fún gbogbo wa. Nínú Osù tuntun yìí, àìsàn kò níí jé ìpín enìkóòkan wa. Eni yòówù tí àìlera bá n dà láàmú, Olódùmarè yóò so ó dèrò. A kò níí rí ìjà ìgbóná. Bí ó tilè wù kí ilé ó gbóná tó, Oba Adédàá yóò so ó dèrò. Àìsàn tí n gba oúnje lénu eni kò níí se wa, èyí tí n gba apá, esè, àti gbogbo èyà ara lówó eni kò níí jé ìpín wa nínú Osù yii. Àjíñde ara yó máa jé o.

Ilé tútù
Ònà tútù
A dí fá fún Olúweri-Mògétì
Àtòjò
Àtèrún
Ilé Olúweri kì í gbóná…

Ilé àti ònà kò níí gbóná mó wa nínú Osù yìí..

About Awoyemi Bamimore

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

“Ìyálóde, Eléékò & The Heavenly Companions: Discover the Mysterious Classes of Egbe in Yoruba Tradition”

Classes of Egbe (Heavenly Mate of Every Human) Also known as Alaragbo in some areas of Yoruba land, Egbe is generally more associated with children than with adults according to Eji-Ogbe. Based on the character traits of human on Earth, the Yoruba have classified Egbe into different categories. Ìyálóde Ìyálóde is regarded as the leader of Egbe on Earth. Leadership quality is most evident characteristic of this class of Egbe. Going by the name, it may appear that only females ...