Home / News From Nigeria / Breaking News / Àwòrán tuntun tokotayà tí won sèsè fé ara won léyìn tí won ti wà gégé bí Òré tímótímó.

Àwòrán tuntun tokotayà tí won sèsè fé ara won léyìn tí won ti wà gégé bí Òré tímótímó.

Àwòrán kí ó tó di ojó ìgbeyàwó olùgbá bóòlù aláwòn ní Brooklyn, Quincy Acy àti àfésónà rè, Jessica Fuenten tí ó sèsè gbòde kan léyìn ìgbà tí inú arewà ìyàwó àfésónà sì ń dùn, so wípé àwon bèrè gégé bíi Òré tímótímó. Àtìgbà tí àwon ti fé ara àwon, àwon ń gbé pèlú ìdùnú gégé bí a ti ri nínú àwòrán ìsàlè yìí. E wo irú ìdùnú tí omobìnrin yí kò bá pàdánù tí kò bá gbà kí won fé ara won sùgbón tí won jo jé Òré Lásán …

About Awoyemi Bamimore

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

Iṣẹṣe Kọ́jọ́dá/calendar – Fún Oṣù Ẹ̀bìbí/May 2025.

TÍ OSU TITUN BÁ DÉ, ARÁYÉ MÁA Ń YỌ̀ MỌ́ NI, WỌN MÁA BÁ GBOGBO WA YỌ AYỌ̀ IRE NÍNÚ OSU TITUN YÍÌ, PẸ̀LÚ ÀṢẸ ELÉDÙMARÈ . 1. Ọbàtálá/Òrìṣà-ńlá, Ọbalúayé/Ṣàpọ̀nná, Ògìrìyàn, Egúngún, Ìyàmi Àjẹ́. 2. Ifá, Ọ̀rúnmìlà, Èṣù-Ọ̀dàrà, Orí, Odù, Ọ̀ṣun, Ajé-Olókun, Ọ̀sányìn, Kórì, Ẹgbẹ́. 3. Ògún, Ìja, Ọ̀ṣọ́ọ̀sì, Erinlẹ̀, Òrìṣà Oko. 4. Jàkùta/Ṣàngó, Ọya, Aganjú, Yemọja, Ìbejì, Nàná-Bùkúù. 5. Ọbàtálá/Òrìṣà-ńlá, Ọbalúayé/Ṣàpọ̀nná, Ògìrìyàn, Egúngún, Ìyàmi Àjẹ́. 6. Ifá, Ọ̀rúnmìlà, Èṣù-Ọ̀dàrà, Orí, Odù, Ọ̀ṣun, Ajé-Olókun, Ọ̀sányìn, Kórì, Ẹgbẹ́. 7. Ògún, Ìja, ...