Home / Art / Àṣà Oòduà / Babajide Sanwoolu àti Obafemi Hamzat pàdé àwon ìlúmòóká Òsèré.

Babajide Sanwoolu àti Obafemi Hamzat pàdé àwon ìlúmòóká Òsèré.

Babajide Sanwoolu àti Obafemi Hamzat pàdé àwon ìlúmòóká Òsèré.
Omo egbé APC tí won yàn láti díje fún ipò Gómìnà ní ìpínlè Eko, tí a mò sí Babajide Sanwoolu àti akegbé rè tí òun a máa jé, Omòwé Obafemi Hamzat ní ìlú Èkó ní àná pàdé àwon gbajúgbajà àti àwon òsèré nlá nlá.
Won sòrò nípa ètò orò ajé to ìpínlè Èkó ní ìgbà ti won.Àwon òsèré bíi Yinka Quadri, Adebayo Salami (Oga Bello), Jide Kosoko àti béè béè lo.

About Awoyemi Bamimore

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

“Ìyálóde, Eléékò & The Heavenly Companions: Discover the Mysterious Classes of Egbe in Yoruba Tradition”

Classes of Egbe (Heavenly Mate of Every Human) Also known as Alaragbo in some areas of Yoruba land, Egbe is generally more associated with children than with adults according to Eji-Ogbe. Based on the character traits of human on Earth, the Yoruba have classified Egbe into different categories. Ìyálóde Ìyálóde is regarded as the leader of Egbe on Earth. Leadership quality is most evident characteristic of this class of Egbe. Going by the name, it may appear that only females ...