Home / Art / Àṣà Oòduà / E wo nkan tí ilé-èkó gíga ifáfitì ti ìlú Èkó tí a mò sí UNILAG se! Sé eléyìí kò ní jé kí àwon òdómobìnrin wa n’íìfé ohun afefe yèyè si báyìí.

E wo nkan tí ilé-èkó gíga ifáfitì ti ìlú Èkó tí a mò sí UNILAG se! Sé eléyìí kò ní jé kí àwon òdómobìnrin wa n’íìfé ohun afefe yèyè si báyìí.

   Nígbà míràn kò ye kí á bá àwon òdómobìnrin wa tí won n’íìfé ohun ayé wí jù, nígbà tí ó jé wípé àwon àwùjo wa kò kúkú mú orí eni tí n se isé takuntakun wú. Ká sisé kára bí eni máa kú, kí won bò wá lówó àti kí á fi àkókò sòfò láti múra láti fi dàbí egbin, kí a sì gba èbùn gbàngba ! Sí ò .

Eni tí ó gba òdómobìnrin arewà jùlo àti òdómokùnrin arewà jùlo ti ilé-èkó gíga ifáfitì ti ìlú Èko ní odún 2014 gba okò bògìnì tí eni tí ó sì mo ìwé jù gba èbún laptop.

Send Money To Nigeria Free

About Awoyemi Bamimore

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

The Èkó(s) of the Oòduà (Yorùbá) Homeland.

Èkó-Ènde (Ìfẹ́lódùn LGA, State of Ọ̀ṣun)Èkó-Àkéte (Lagos Island LGA, Lagos State)Èkó-Àjàlá (Ìfẹ́lódùn LGA, State of Ọ̀ṣun)Èkó – Efun ( Amongst The Olukumi of Delta state) 2021 Edition of the Ọ̀tín-Èkó Festival where the Ọ̀tín River is celebrated by the Èkó people around the River in Ọ̀ṣun. Ọtín River is a very important one in Yorùbá history. It was the river that drowned the highest number of terrible invaders of the Homeland in the Jálumi war of November 1, 1878.In fact, ...