Home / Art / Àṣà Oòduà / Èèmò lukutu pébé ní ilé-èkó gíga ìfáfitì ti Ilé-ifè : Nígbà tí akékòó kan ya wèrè nígbà tí ó n kàwé lówó.

Èèmò lukutu pébé ní ilé-èkó gíga ìfáfitì ti Ilé-ifè : Nígbà tí akékòó kan ya wèrè nígbà tí ó n kàwé lówó.

Gégé bí a ti mo wípé òkan gbógì ní ilé-èkó gíga Òbafemi Awolowo University (OAU) jé ní orílè èdè Nìjíríà yí.

Sà déédéé ni a gbó wípé arábìnrin kan tí ó jé akékòó ilé-èkó yí ya wèrè látàrí ìwé kíkà nígbá yí ó jé wípé ìdánwò won ti kù sí dèdè.

Ní alé ìjeta ni ìsèlè yí selè, nígbá tí omobìnrin yí sa wèrè tán, ìwé tí ó n kà náà ló fi ñ lu ìlù. Àfi kí elédùà gbàwá ooo.

 

About Awoyemi Bamimore

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

What is Àdìmù?

A few of my friends and students in the diaspora had asked me this question countless times, and I think it’s high time we discussed it.Please note that this is not an attempt to discredit or invalidate any practice or belief; this piece is just for us to educate one another.Now, in the Yoruba language, what does Adimu mean, or where does it originate from?Àdimu means “To hold.”The full word is Adimula, which means “to hold and prosper.”So, where does ...