Home / Art / Àṣà Oòduà / Grace Oyelude, obìnrin àkókó tí Ó kókó gba àmì èye omidan arewà ní orílè èdè Nìjíríà.

Grace Oyelude, obìnrin àkókó tí Ó kókó gba àmì èye omidan arewà ní orílè èdè Nìjíríà.

Grace Oyelude, obìnrin àkókó tí Ó kókó gba àmì èye omidan arewà ní orílè èdè Nìjíríà.

Ìyáawa Grace Atinuke, tí won bí ní ojó kerìndínlógún osù beelu ní odún 1931, tí a mò sí eni tí ó kókó gba àmì èye omidan arewà ní orílè èdè Nìjíríà ní odún 1952.

Lóòtó ìlú Kogi ní won tí bí màmá, ìyáawa oyelude ni a bí sí ilé Kano sí ìdílé James Adeleye Olude àti Marthan Dantu tí àwon méjèèjì jé omo bíbí Isanlu, tí a mò sí ìpínlè Kogi báyìí.

Arewà ni ìyá ní tòótó e wo bí won se tún re wà.

About Awoyemi Bamimore

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

Happy New Calendar Year!!! It is 10068 of the Oodua Yoruba Calendar-–-KỌ́JỌ́DÁ

The Yoruba traditional calendar, called Kọ́jọ́dá, starts the new year on June 3rd and ends on June 2nd the following year. It’s a lunar calendar with a 4-day week (each day honoring different Orisa), 7 weeks in a month, and 13 months in a year—so their year is 364 days long. The months and weeks are deeply tied to farming cycles, moon phases, and religious rituals.The traditional Yoruba week has four days. The four days that are dedicated to the ...