Home / Art / Àṣà Oòduà / Igbe aye Oba Lamidi Olayiwola Atanda Adeyemi dun bi oyin

Igbe aye Oba Lamidi Olayiwola Atanda Adeyemi dun bi oyin

Oba_Lamidi_Olayiwola
Laipe yii ni Oba Lamidi Adeyemi, Alaafin Oyo pe eni odun metadinlogorin. E le ka iroyin naa nibi:

Lara awon foto ojo ibi baba mi-in to te wa lowo ni eyi ti baba ya pelu Olori Badirat Adeyemi, olori baba to kere ju lo.

Bi Oosa Oyo tile ti dagbalagba, Olori Badirat, eni to sese wo ile iwe giga Ifafiti lodun yii ko je ki ara baba o darugbo kiakia pelu awon itoju orisiirisii ti n fi n te baba lorun niyewu. Eleyii to si n mu baba dabi omo tuntun jojolo.

Ti won ba ni Oba wo lo jaye ju laye? Walahi, Oba Lamidi ni!

Orisun

About admin

One comment

  1. Aisha M.B.P.

    Oba Lamidi with his very young child bride.Thats okay I guess cos he’s not from the North of Nig.

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

Onibode

The Tale of Oníbodè Lálúpọn and the Dundun Drummer

Long ago, in the ancient city of Ibadan, famed for its warriors and sprawling hills, there lived a gatekeeper-warrior stationed in the outskirts of the city, in a settlement known as Lálúpọn on the way to Ìwó. His duty was clear: to watch the road, collect tolls, and guard the passage of traders and travellers entering and leaving Ibadan. Because of this important task, people called him Oníbodè Lálúpọn; the Gatekeeper of Lálúpọn. Though he was not particularly comely, Oníbodè ...