Home / Art / Àṣà Oòduà / Igbe aye Oba Lamidi Olayiwola Atanda Adeyemi dun bi oyin

Igbe aye Oba Lamidi Olayiwola Atanda Adeyemi dun bi oyin

Oba_Lamidi_Olayiwola
Laipe yii ni Oba Lamidi Adeyemi, Alaafin Oyo pe eni odun metadinlogorin. E le ka iroyin naa nibi:

Lara awon foto ojo ibi baba mi-in to te wa lowo ni eyi ti baba ya pelu Olori Badirat Adeyemi, olori baba to kere ju lo.

Bi Oosa Oyo tile ti dagbalagba, Olori Badirat, eni to sese wo ile iwe giga Ifafiti lodun yii ko je ki ara baba o darugbo kiakia pelu awon itoju orisiirisii ti n fi n te baba lorun niyewu. Eleyii to si n mu baba dabi omo tuntun jojolo.

Ti won ba ni Oba wo lo jaye ju laye? Walahi, Oba Lamidi ni!

Orisun

About admin

One comment

  1. Aisha M.B.P.

    Oba Lamidi with his very young child bride.Thats okay I guess cos he’s not from the North of Nig.

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

“Ìyálóde, Eléékò & The Heavenly Companions: Discover the Mysterious Classes of Egbe in Yoruba Tradition”

Classes of Egbe (Heavenly Mate of Every Human) Also known as Alaragbo in some areas of Yoruba land, Egbe is generally more associated with children than with adults according to Eji-Ogbe. Based on the character traits of human on Earth, the Yoruba have classified Egbe into different categories. Ìyálóde Ìyálóde is regarded as the leader of Egbe on Earth. Leadership quality is most evident characteristic of this class of Egbe. Going by the name, it may appear that only females ...