Home / Art / Àṣà Oòduà / Kò sí ilé tàbí só̩ò̩bù tí a kò le fo̩ láti ké̩rù òfin – Àjo̩ Customs
customu

Kò sí ilé tàbí só̩ò̩bù tí a kò le fo̩ láti ké̩rù òfin – Àjo̩ Customs

Awon ajo asobode ile Nigeria ti gbogbo eniyan mo si Customs ni won n ba awon oniroyin soro ni ipinle Adamawa pe, ko si ile tabi soobu ti awon ko le ja tabi fo ti o ba ye.
Won ni gbogbo eda tabi onisowo fayawo ti awon ba kefin pe o keru wole lona aito ni awon le fagidi ja ile tabi soobu re ki awon si lo awon ero ofin naa lo.


Gege bi iko ti Ogbeni Kamarudeen Olumon dari ni ipinle Adamawa se salaye. O ni bi awon se n ge awon onifayawo lowo ni won n bo oruko.
O ni gbogbo ogbon alumokoroyi ni won mo ti won si fi n koja wole. O ni ofin abala 147 ajo Customs gba awon laaye lai gbase lati ibikankan lati lo ko iru oja bee.

Awon ara oja Mubi ni ipinle naa rawo ebe si ijoba apapo ki o jowo si oju aanu wo awon nitori pe opo onisowo lo dawojo lati lo ra oja ti awon ajo naa gbese le. Won ni awon ko tun je fi iru aso bee seegun mo.
Awon ajo yii ko gbo ebe rara, gbogbo iresi, ororo ati awon nnkan ile okeere miran ti won ba ninu oja Mubi naa ni won ko.

Yinka Alabi

About ayangalu

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

History 101: What it takes to be a MENTALLY ENSLAVED FOOL in Your ancestral Land.

History 101: What it takes to be a MENTALLY ENSLAVED Harlequin in Your ancestral Land.

The quote for today is a page from Toyin Falola’s book, ‘Yoruba Warlords of the 19th Century’. To a lot of Yoruba Muslims. Islam means servitude to Usman Dan Fodio’s estate at Sokoto. They indulge in the same idiocy that led to the fall of the great Hausa civilization. Many Yoruba Muslims from Oyo are a dangerously brainwashed set of people that would pose future danger for the preservation of Yorubaland like their ancestors who pledged allegiance to Ilorin and ...