Home / Art / Àṣà Oòduà / Nìjíríà ìgbà wo ni a ó gba òmínira.

Nìjíríà ìgbà wo ni a ó gba òmínira.

Nìjíríà ńlé sunkún
Àwon èèyàn ibè ò ye é rérìn-ín òfò
Èrín òfò tí won rò pé ti ìdùnú ní se

Nìjíríà ìlú tí òmínira rè ti di omi ìnirà
Atún ti wálé
Ojó wo ni àwa náà yóò gba ife gbogbo àgbáyé
Ó mà se o!

Argentina tún ko bò wá láàná, won tún lé wa léré wálé láti odún 1995 ni wón kúkú ti ń fó wa lénu.

Ikò super Eagles ti láwon ò super mó oo A ti dágbére fún won ní Russia

Nìjíríà ìlú olómìnira.

About Awoyemi Bamimore

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

What is Àdìmù?

A few of my friends and students in the diaspora had asked me this question countless times, and I think it’s high time we discussed it.Please note that this is not an attempt to discredit or invalidate any practice or belief; this piece is just for us to educate one another.Now, in the Yoruba language, what does Adimu mean, or where does it originate from?Àdimu means “To hold.”The full word is Adimula, which means “to hold and prosper.”So, where does ...