Home / Art / Àṣà Oòduà / Nìjíríà ìgbà wo ni a ó gba òmínira.

Nìjíríà ìgbà wo ni a ó gba òmínira.

Nìjíríà ńlé sunkún
Àwon èèyàn ibè ò ye é rérìn-ín òfò
Èrín òfò tí won rò pé ti ìdùnú ní se

Nìjíríà ìlú tí òmínira rè ti di omi ìnirà
Atún ti wálé
Ojó wo ni àwa náà yóò gba ife gbogbo àgbáyé
Ó mà se o!

Argentina tún ko bò wá láàná, won tún lé wa léré wálé láti odún 1995 ni wón kúkú ti ń fó wa lénu.

Ikò super Eagles ti láwon ò super mó oo A ti dágbére fún won ní Russia

Nìjíríà ìlú olómìnira.

About Awoyemi Bamimore

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

Lati Ọwọ Aworosaṣa Moyọ Okediji

Cultural War Rages on: Africa’s Civilizations Are Being Erased—who Will Teach African Artists?

AFRICAN AESTHETICS Many universities in the West are developing core curriculum programs focused on “Western Civilization,” while increasingly purging African, African Diaspora, Asian, and other civilizations from their programs. The West focusing on Western Civilization is appropriate. The days of African and African Diaspora Studies seem numbered. At the same time, Africana artists are producing contemporary works like never before. What are these Africana artists going to read? Are they going to study Western Civilization only, without any understanding of ...