Home / Art / Àṣà Oòduà / Olólùfé gbajúgbajà olórin Davido sòrò nípa irun abíyá rè tí kò fá. “Ra igi fífá-irun àádóta náírà (#50)nínú bílíònù lónà ogbòn re.
davido

Olólùfé gbajúgbajà olórin Davido sòrò nípa irun abíyá rè tí kò fá. “Ra igi fífá-irun àádóta náírà (#50)nínú bílíònù lónà ogbòn re.

Àwon olólùfé gbajúgbajà olórin tí a mò sí Davido sòrò nípa irun abíyá rè tí kò fá. “Ra igi fífá-irun àádóta náírà (#50)nínú bílíònù lónà ogbòn re.
Davido le jé eni tí àwon ènìyàn féràn sùgbón ìyan kò so pé ó kojá ìbáwí, tí ó bá ye kí á ba wí…

Gbajúgbajà olórin, pín àwòrán ara rè tí kò wo aso sí orí èro ayélujàra (instagram) lésèkesè ni àwon èèyàn ti ń bu tí won sì gbà á ní ìmòràn látàrí rírí àbùkùn kan tàbí méji nípa àwòrán náà.

Nígbà tí inú àwon kan kò dùn sí àwòrán tí ó yà s’ára àwon míràn gbà á ní ìmòràn kí ó lo fá irun abíyá rè tí ó ti kún

Continue after the page break for English Version

About Lolade

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

“Ìyálóde, Eléékò & The Heavenly Companions: Discover the Mysterious Classes of Egbe in Yoruba Tradition”

Classes of Egbe (Heavenly Mate of Every Human) Also known as Alaragbo in some areas of Yoruba land, Egbe is generally more associated with children than with adults according to Eji-Ogbe. Based on the character traits of human on Earth, the Yoruba have classified Egbe into different categories. Ìyálóde Ìyálóde is regarded as the leader of Egbe on Earth. Leadership quality is most evident characteristic of this class of Egbe. Going by the name, it may appear that only females ...