Home / Art / Àṣà Oòduà / Omobìnrin kan ní ilè Akwa Ibom ni àwon ebí rè ti fi sílè fún ikú sùgbón olùrànlówó kan ti gbà á kalé.

Omobìnrin kan ní ilè Akwa Ibom ni àwon ebí rè ti fi sílè fún ikú sùgbón olùrànlówó kan ti gbà á kalé.

    Àwon òsìsé tí ó ranilówó láti orílè èdè Denmark àti olùdásílè ètò ìsàkóso àwon èwe (Children’s Aid Education and Development Foundation (ACAEDF), Anja Ringgren lovên, ti ran omobìnrin odún méwàá lówó, omo tí a mò sí Deborah, èyí tí àwon ebí rè fi sílè fún ikú ní òpópónà . omobìnrin yí ni a gbô wípé ó ma bèrè ilé-èkó rè ní òsè tí ó n bò kí á dúpé lówó Anja Rimggren Lovên.

About Awoyemi Bamimore

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

What is Àdìmù?

A few of my friends and students in the diaspora had asked me this question countless times, and I think it’s high time we discussed it.Please note that this is not an attempt to discredit or invalidate any practice or belief; this piece is just for us to educate one another.Now, in the Yoruba language, what does Adimu mean, or where does it originate from?Àdimu means “To hold.”The full word is Adimula, which means “to hold and prosper.”So, where does ...