Home / Art / Àṣà Oòduà / Omobìnrin kan ní ilè Akwa Ibom ni àwon ebí rè ti fi sílè fún ikú sùgbón olùrànlówó kan ti gbà á kalé.

Omobìnrin kan ní ilè Akwa Ibom ni àwon ebí rè ti fi sílè fún ikú sùgbón olùrànlówó kan ti gbà á kalé.

    Àwon òsìsé tí ó ranilówó láti orílè èdè Denmark àti olùdásílè ètò ìsàkóso àwon èwe (Children’s Aid Education and Development Foundation (ACAEDF), Anja Ringgren lovên, ti ran omobìnrin odún méwàá lówó, omo tí a mò sí Deborah, èyí tí àwon ebí rè fi sílè fún ikú ní òpópónà . omobìnrin yí ni a gbô wípé ó ma bèrè ilé-èkó rè ní òsè tí ó n bò kí á dúpé lówó Anja Rimggren Lovên.

About Awoyemi Bamimore

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

Lati Ọwọ Aworosaṣa Moyọ Okediji

Cultural War Rages on: Africa’s Civilizations Are Being Erased—who Will Teach African Artists?

AFRICAN AESTHETICS Many universities in the West are developing core curriculum programs focused on “Western Civilization,” while increasingly purging African, African Diaspora, Asian, and other civilizations from their programs. The West focusing on Western Civilization is appropriate. The days of African and African Diaspora Studies seem numbered. At the same time, Africana artists are producing contemporary works like never before. What are these Africana artists going to read? Are they going to study Western Civilization only, without any understanding of ...