Home / Art / Àṣà Oòduà / Omobìnrin kan ní ilè Akwa Ibom ni àwon ebí rè ti fi sílè fún ikú sùgbón olùrànlówó kan ti gbà á kalé.

Omobìnrin kan ní ilè Akwa Ibom ni àwon ebí rè ti fi sílè fún ikú sùgbón olùrànlówó kan ti gbà á kalé.

    Àwon òsìsé tí ó ranilówó láti orílè èdè Denmark àti olùdásílè ètò ìsàkóso àwon èwe (Children’s Aid Education and Development Foundation (ACAEDF), Anja Ringgren lovên, ti ran omobìnrin odún méwàá lówó, omo tí a mò sí Deborah, èyí tí àwon ebí rè fi sílè fún ikú ní òpópónà . omobìnrin yí ni a gbô wípé ó ma bèrè ilé-èkó rè ní òsè tí ó n bò kí á dúpé lówó Anja Rimggren Lovên.

Send Money To Nigeria Free

About Awoyemi Bamimore

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

The Èkó(s) of the Oòduà (Yorùbá) Homeland.

Èkó-Ènde (Ìfẹ́lódùn LGA, State of Ọ̀ṣun)Èkó-Àkéte (Lagos Island LGA, Lagos State)Èkó-Àjàlá (Ìfẹ́lódùn LGA, State of Ọ̀ṣun)Èkó – Efun ( Amongst The Olukumi of Delta state) 2021 Edition of the Ọ̀tín-Èkó Festival where the Ọ̀tín River is celebrated by the Èkó people around the River in Ọ̀ṣun. Ọtín River is a very important one in Yorùbá history. It was the river that drowned the highest number of terrible invaders of the Homeland in the Jálumi war of November 1, 1878.In fact, ...