Home / Art / Àṣà Oòduà / Owó✋lá fi n sisé owó
owo

Owó✋lá fi n sisé owó

Esè la fí ñ rìnnà Olà
Àtowó àtesè ki Elédùmarè má gba ìkankan nínú rè lówó wa, ká lè fi rí nñkan Ajé kó jo…

Asáré pajé
Arìngbèrè polà
Òhun ewà ní wón jó n wòlú
Adífáfún Ògbìngbìn kan Ògbìngbìn kàn
Tó re inú ìrókò lo ree múlé si
Tó n polówó ajé tantantan.
Ó ní Alájé eni kìí la, kínú ó bínii
Ñjé kí là ñ jé lótù Ifè tájé fi n yale ëni?
Ògèdè òmìnì là ñ jé lótù Ifè tájé fi nyale eni ..

*Lónìí tí osù tuntun bèrè, Ajé yó fi ilé gbogbo wa se ibùgbé ooo… Àse..*

*ooduarere kí i yín, wípé a kú osú tuntun Ooo*

About ayangalu

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

History 101: What it takes to be a MENTALLY ENSLAVED FOOL in Your ancestral Land.

History 101: What it takes to be a MENTALLY ENSLAVED Harlequin in Your ancestral Land.

The quote for today is a page from Toyin Falola’s book, ‘Yoruba Warlords of the 19th Century’. To a lot of Yoruba Muslims. Islam means servitude to Usman Dan Fodio’s estate at Sokoto. They indulge in the same idiocy that led to the fall of the great Hausa civilization. Many Yoruba Muslims from Oyo are a dangerously brainwashed set of people that would pose future danger for the preservation of Yorubaland like their ancestors who pledged allegiance to Ilorin and ...