Home / Art / Àṣà Oòduà / olópàá kan ní Enugu ti mú àwon òdóbìnrin méjì nígbà tí won n rìn l’ójú ònà látàrí aso ìwòkuwò tí won wò.

olópàá kan ní Enugu ti mú àwon òdóbìnrin méjì nígbà tí won n rìn l’ójú ònà látàrí aso ìwòkuwò tí won wò.

Gégé bí eni tí ojú rè to se so, tí ó sì gbe sí orí èro ayélujára se so, olópàá kan ní ìpínlè Enugu ni a ti fi èsùn kàn wípé ó mú àwon òdóbìnrin méjì tí won wò aso ìwòkuwò.
A gbó wípé ìsèlè yí selè ní ojó ajé (Monday), ogún’jó osù kokànlá (November 20) ní òpópónà Garrison ní Enugu.

About Awoyemi Bamimore

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

Lati owo Aworosasa Moyo Okediji

Cultural War Rages on: Africa’s Civilizations Are Being Erased—who Will Teach African Artists?

AFRICAN AESTHETICS Many universities in the West are developing core curriculum programs focused on “Western Civilization,” while increasingly purging African, African Diaspora, Asian, and other civilizations from their programs. The West focusing on Western Civilization is appropriate. The days of African and African Diaspora Studies seem numbered. At the same time, Africana artists are producing contemporary works like never before. What are these Africana artists going to read? Are they going to study Western Civilization only, without any understanding of ...