Home / Art / Àṣà Oòduà / Àwon Akékòó Ogbà Fémi jà fún ètó won

Àwon Akékòó Ogbà Fémi jà fún ètó won

Bí a bá pè é ní ìjà láàrin akékòó eka èkó gèésì (Department of English ) àti ti àwon eka èkó nípa òfin (faculty of law) ti ilé-èkó gíga ifáfitì ti Obafemi Awolowo university wo ìyá ìjàkadì Látàrí wípé àwon kan kò jé kí àwon kan wo yàrá ìkàwé.

Gégé bí a ti gbo, àwon law ti parí isé ti won tí Ó sì ye kí won jáde fún àwon English láti jé kí won w’olé, sùgbón tí àwon law kò láti yára jáde nígbà tí Ó jé wípé olùkó àwon English sì ti de láti kó won, Lóòtó èyí ló fa ìjà.

Ìjà yí kì bá tí selè tí ó bá jé wípé àwon alákóso ogbà ti pèsè àyè tí Ó tó fún awon akékòó láti kékòó.

About Awoyemi Bamimore

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

Omisore

Àwàdà kẹrí-Kẹrì ni àwọn kọmití tó ní mi ò lè díje du ipò gómìnà APC ni 2026 n ṣe – Omisore

Yínká Àlàbí Awọn kọmiti to n ṣe àyẹ̀wò awọn oludije du ipo gomina labẹ ẹgbẹ́ oselu APC ti ja igbakeji gomina tẹlẹ ni ipinle Osun, Alagba Iyiola Omisore ati awọn mẹfa miiran.Wọn ni iwe wọn ko pe lati dije du ipo gomina ipinlẹ naa. Awọn mẹfẹẹfa to ku naa ni – Babatunde Oralusi, Oyedotun Babayemi, Dr. Akin Ogunbiyi, Benedict Alabi, Adegoke Rasheed Okiki, ati Senator Babajide Omoworare.Iyiola Omisore ni awada Kẹri-Kẹri ni awọn kọmiti naa n se nitori ti wọn ...