Home / Art / Àṣà Oòduà / Olò̩tè̩ èmi àti Aláàfin máa fojú ba ilé-e̩jó̩ – Wasiu Ayinde
wasiu

Olò̩tè̩ èmi àti Aláàfin máa fojú ba ilé-e̩jó̩ – Wasiu Ayinde

Gbajugbaja olorin fuji ti ina orin re si n jo lowo bayii ni o ti fa ibinu yo nigba ti won fesun kan an pe, o ni asepo pelu okan ninu awon olori Alaafin ti ilu Oya, Oba Lamide Adeyemi 111.


Wasiu ayinde ni lati igba ti oun ti di Mayegun ile Yoruba ni awon ota ti n gbogun, won n wa gbogbo ona lati ba oun loruko je, paapaa julo lodo eni to mu oun bi omo, iyen “Iku baba yeye” Alaafin Oyo.


O ni oun to je omo Yoruba gidi to mo ofin to si tun mo eewo. Kin ni oun fe wa de odo olori Badirat Ajoke? O ni pelu bi obinrin tile ti po to laye yii.


Wasiu Ayinde ni oun ko le fi oju oloore gungi.
K1 De Ultimate ni iwadii to gbopan ti n lo lowo lati fi oju asebi han. O ni oun si se ileri pe elese ko ni lo lai je iya nitori pe ile-ejo ni awon maa gba lo ti eni ibi naa si maa ko eri re jade.


Ogbeni Kunle Rasheed to je okan ninu awon alukoro Alhaji Wasiu Ayinde lo fi ise naa je faraye.

About ayangalu

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

History 101: What it takes to be a MENTALLY ENSLAVED FOOL in Your ancestral Land.

History 101: What it takes to be a MENTALLY ENSLAVED Harlequin in Your ancestral Land.

The quote for today is a page from Toyin Falola’s book, ‘Yoruba Warlords of the 19th Century’. To a lot of Yoruba Muslims. Islam means servitude to Usman Dan Fodio’s estate at Sokoto. They indulge in the same idiocy that led to the fall of the great Hausa civilization. Many Yoruba Muslims from Oyo are a dangerously brainwashed set of people that would pose future danger for the preservation of Yorubaland like their ancestors who pledged allegiance to Ilorin and ...