Ìjàm̀bá iná se ò̩nà Eko sí Ibadan ati Ibadan sí Eko paÌròyìn láti o̩wó̩ Yínká ÀlàbíOro gbogbo kii se lori alabahun ni opopona Eko si Ibadan ati Ibadan si Eko. Lati igba ti awon Julius Berger ti bere ona naa ...
Read More »
Àṣà Oòduà, Asa Ibile Oòduà. Oòduà (Yoruba) je okan ninu awon eya ti o laju ju lode aye yi. Lati igba ti alaye ti daye ni won ti ni eto ati ilana to kun nipa ohun gbogbo ti won nse ni igbesi ayee won.
ayangalu Comments Off on Ìjàm̀bá iná se ò̩nà Eko sí Ibadan ati Ibadan sí Eko pa
Ìjàm̀bá iná se ò̩nà Eko sí Ibadan ati Ibadan sí Eko paÌròyìn láti o̩wó̩ Yínká ÀlàbíOro gbogbo kii se lori alabahun ni opopona Eko si Ibadan ati Ibadan si Eko. Lati igba ti awon Julius Berger ti bere ona naa ...
Read More »ayangalu Comments Off on Sofia Kenin gba ife è̩ye̩ ìdíje Australia open 2030
Omo orileede American, Sofia Kenin, ti fi ebun re han si gbogbo agbaye pelu bi o se bori ifigagbaga asekagba laarin oun ati omo orileede Spain
Read More »ayangalu Comments Off on Akiyesi Pataki
Arákùnrin oníṣègùn oyinbo tó jẹ́ ọmọ bíbí Nigeria to wá n’ilu USA, fi ọrọ ìyànjú yí ranṣẹ fún anfaani ara wa. Jọ̀wọ́ ká, kí ó sì mú lo fún ìtọ́jú ara rẹ. Dr. A. Malgwi Ọna ti àwọn ọdọ wá ...
Read More »ayangalu Comments Off on Sanwo-olu dáhùn ìbéèrè okada ló̩wó̩ aké̩kò̩ó̩ Chrisland
Sanwo-olu dáhùn ìbéèrè okada ló̩wó̩ aké̩kò̩ó̩ ChrislandLáti o̩wó̩ Yínká ÀlàbíGomina Babajide Sanwo-olu ti ipinle Eko lo n dahun orisiirisii ibeere lowo awon akekoo ile-iwe Chrisland to wa ni ilu Opebi ni Eko, nigba ti o gba won lalejo ni oni ...
Read More »ayangalu Comments Off on Odù kan gorí àtẹ,Ọdẹ́gbèmí Ọdẹ́gbolá11 goróyè Àràbà nílẹ̀ẹ̀bàdàn
Odù kan gorí àtẹ,Ọdẹ́gbèmí Ọdẹ́gbolá11 goróyè Àràbà nílẹ̀ẹ̀bàdàn Onírúurú aṣọ lára alágẹmọ, onírúurú ètè lápèjẹ sààráà lọ́jọ́ tí orí mádé, w nu agogo idẹ ní tií wà, ọrùn w’ọnú lèjígbà ìlẹ̀kẹ̀, àní lọ́jọ́ tó mú ìbàdì Àràbà Ògbó awo ,Oloye ...
Read More »ayangalu Comments Off on Nnkan méje ti yóò yipada àti meje ti kò ni yi pada lẹ́yìn ti ilẹ Gẹ̀ẹ́si ti kuro labẹ EU
Lẹ́yin ọdún mẹ́ta lílọ bibọ̀ lórí ọ̀rọ̀ Brexit, ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́ṣì padà kúrò lábẹ́ EU ní aago mọ́kànlá alẹ́ ọjọ́ Jimọ ọjọ́ kọkànlélọ́gbọ̀n Oṣù kínní ọdún 2020.
Read More »ayangalu Comments Off on Kí gbogbo àwọn olórí ààbò lọọ rọ́kún nílé – Ilé ìgbìmọ̀ asojú
Kí gbogbo àwọn olórí ààbò lọọ rọ́kún nílé – Ilé ìgbìmọ̀ asojúLáti ọwọ́ Yínká Àlàbí Abajade ipade ile igbimo asoju to wa ni Abuja ni “a kuku joye san ju enu mi ko ka ilu lo”. Won ni ki gbogbo ...
Read More »ayangalu Comments Off on Jonathan sàbẹ̀wò sí Buhari
Ara iroyin yajoyajo to wole ni abewo ti Aare ana, Omowe Goodluck Jonathan se si Aare Mohammadu Buhari ni Aso Villa to wa ni oluulu Naijiria ni Abuja. Ipade bonkele ni ipade yii nitori pe awon mejeeji tilekun mori ni, ...
Read More »ayangalu Comments Off on Ìdíle Saraki àti ìjọba ìpínlẹ̀ Kwara dájọ́ ìpàdé
Lẹ́yìn tí Ìjọba Ìpínlẹ̀ Kwara ti tẹ̀lé òfin tí wọ́n wo ohun ìní ìdílé Saraki èyí tí wọ́n ń pé ibẹ̀ ni Ilé Arúgbó ní ìlú Ilorin, ìpínlẹ̀ Kwara, gbogbo àwọn tọ́rọ̀ kan nínú rẹ̀ ti wá gbà láti yanjú aáwọ̀ láì ti ọwọ́ Ilé ẹjọ́ bọ̀ ọ́ mọ́.
Read More »ayangalu Comments Off on Àwọn Yèyélórìṣà, Akirè Shrine Ilé Ifẹ̀, 2003.
Pitcture was taken by Prof. Moyo Okediji in 2003, he returned to find the group in 2015. But for the two women at the extreme left, all the others had transitioned.
Read More »
Ọmọ Oòduà Naija Gist | News From Nigeria | Entertainment gist Nigeria|Networking|News.. Visit for Nigeria breaking news , Nigerian Movies , Naija music , Jobs In Nigeria , Naija News , Nollywood, Gist and more