Láìpé ni BankyW àti Adesua Etomi se ìgbéyàwó ìbílè won ní ìlú èkó, àwon tokotayà ti wá t’owó bo ìwé èrí ìgbéyàwó wo, won ti di oko àti aya . Won ti se ìgbéyàwó alárédè báyìí. Èyí da ...
Read More »
Awoyemi Bamimore Comments Off on BankyW àti Adesua Etomi ti wá di tokotayà báyìí, won sì ti ti fi fi owó sí ìwé èrí ìgbéyàwó won.
Láìpé ni BankyW àti Adesua Etomi se ìgbéyàwó ìbílè won ní ìlú èkó, àwon tokotayà ti wá t’owó bo ìwé èrí ìgbéyàwó wo, won ti di oko àti aya . Won ti se ìgbéyàwó alárédè báyìí. Èyí da ...
Read More »Awoyemi Bamimore Comments Off on Zion Ayo Balogun ; Wizkid so omo rè okùnrin tí Jada pollock bí fún ní orúko.
A gbó láìpé la gbó wípé Wizkid ti kí omo tuntun káàbò tí alákoso rè, Jada Pollock bí fun. Òótó ni èyí, Wizkid ti ri dájú wípé omo òun ni , ó sì ti so omo náà l’órúko “Zion ...
Read More »Awoyemi Bamimore Comments Off on “Ó ye kí obìnrin náà ní ànfààní àti fé okùnrin Mérin” òdóbìnrin mùsùlùmí yí ló so béè.
9Ò n lò èro ayárabíàsà (Twitter) tí a mò sí Halima ni òpò ti takò látàrí wípé ó so wípé ó ye kí won gba obìnrin náà láyè kí won fé ju okùnrin kan lo. Ní òtító olórun ...
Read More »Awoyemi Bamimore Comments Off on Àwòrán Adesua Etomi níbi ayeye ìgbéyàwó ìsènbáyé rè.
Òsèré tí ó gbajúgbajà, Adesua Etomi tún yo ní àrà òtò, sé e mò wípé òtò l’omo oba n rìn . Ó ti è ti rewà jù òun gan ni a ò bá ma pè ní Òkín l’áwùjo ...
Read More »Awoyemi Bamimore Comments Off on Beverly Naya, Stephanie, Toyin Abraham, Juliet: ta ni ó ró Aso ebí yí jù.
Tani Aso yí dára jù lára rè láàrin àwon arábìnrin arewà méwàá yí. E rò ó e tó mú o, Beverly Naya rewà púpò, Stephanie rè é ojú kò kúrò lára rè, Toyin Abraham dàbí egbin ní tirè, Juliet kò ...
Read More »Awoyemi Bamimore Comments Off on Somkele Iyama wo aso tí kò bo omú ló sí ayeye ìgbéyàwó BankyW àti Adesua Etomi.
Arábìnrin tí ó rewà tí ti jé kí elénu sónu níbi aso tí ó wò tí ó dùn tí ó sì tún se òwón (n se ni ó dàbí eni wípé ó wo bùbá àti ìró)ó wò lo sí ìbí ...
Read More »Awoyemi Bamimore Comments Off on Okùnrin yí ni ó te omú obìnrin yí tí ó sì jé kí òpò ma sòrò .
Okùnrin yí ni ó te omú obìnrin yí tí ó sì jé kí òpò ma sòrò . E gbó kí ló n selè níbi àwòrán yí? Mo ti è rò wípé arábìnrin yí kò ní gbà fún arákùnrin yí, okùnrin ...
Read More »Awoyemi Bamimore Comments Off on Àwòrán Olusegun Obasanjo tí ó yà ní ìgbà tí ó ti pé tí ó yà ní kété tí won fi sílè ní èwòn.
Àwòrán Olusegun Obasanjo tí ó yà ní ìgbà tí ó ti pé tí ó yà ní kété tí won fi sílè ní èwòn. Olusegun Obasanjo níbi ìsìn ìdúpé léyìn ìgbà tí won da sílè l’éwon ní odún 1998. Owó mà ...
Read More »Awoyemi Bamimore Comments Off on Àwon òdó se ayeye ojó ìbí fún Ààre télè, Goodluck Ebele Jonathan ní ìgbà tí ó pé omo ogóta odún (60th).
Ogúnl’ógbòn àwon òdó ni won péjú níbi ayeye ojó ìbí Ààre orílè èdè Nàíjíríà télè, Goodluck Ebele Jonathan láti ba se ayeye ojó ìbí rè nígbà tí ó pé omo ogota odún. E wo àwòrán n’ísàlè .
Read More »Awoyemi Bamimore Comments Off on “Mo máa já we kulè ” Wizkid kìlò fún obìnrin tí ó ní ìfé rè .
Òkan lára àwon Olólùfé obìnrin tí ó ti nífèé Wizkid ti pin sí orí èro ayárabíàsá (Twitter) láti fi èhónu rè hàn wípé òun nífèé Wizkid sùgbón ó so wípé ànfààní nlá ni kí Wizkid fé òun kí ...
Read More »
Ọmọ Oòduà Naija Gist | News From Nigeria | Entertainment gist Nigeria|Networking|News.. Visit for Nigeria breaking news , Nigerian Movies , Naija music , Jobs In Nigeria , Naija News , Nollywood, Gist and more