Ajimobi àti Yinka Ayefele pàdé níbi ayeye Àádòrún odún (90) ojó-ìbí Olúbàdàn. Ìyàlénu ñlá gbáà ni ayeye Àádòrún ojó-ìbí olúbàdàn ti ilè ìbàdàn tí a mò sí Oba Saliu Akanmu Adetunji ní ojó Àìkú. Gómìnà ìjoba ìpínlè Oyo Abiola Ajimobi ...
Read More »
Awoyemi Bamimore Comments Off on Ajimobi àti Yinka Ayefele pàdé níbi ayeye Àádòrún odún (90) ojó-ìbí Olúbàdàn.
Ajimobi àti Yinka Ayefele pàdé níbi ayeye Àádòrún odún (90) ojó-ìbí Olúbàdàn. Ìyàlénu ñlá gbáà ni ayeye Àádòrún ojó-ìbí olúbàdàn ti ilè ìbàdàn tí a mò sí Oba Saliu Akanmu Adetunji ní ojó Àìkú. Gómìnà ìjoba ìpínlè Oyo Abiola Ajimobi ...
Read More »Awoyemi Bamimore Comments Off on Sineto Musiliu Obanikoro ti lo kí Oònirìsà .
Sineto Musiliu Obanikoro ti lo kí Oònirìsà . Sineto Musiliu Obanikoro tí ó jé adarí àwon olúdábòòbò ti orílè èdè Nìjíríà télè ti lo kí baba wa Oònirìsà tí a mò si àrólé odùduwà ní ìlú ilé-ifè ní ojó mélòó ...
Read More »Awoyemi Bamimore Comments Off on Ìròyìn burúkú gbáà ni ó jé nígbà tí a gbó wípé baba omo Bisola tí ó jé òkan lára àwon omo ilé BBNaija télè kú.
Ìròyìn burúkú gbáà ni ó jé nígbà tí a gbó wípé baba omo Bisola tí ó jé òkan lára àwon omo ilé BBNaija télè kú. Ará ilé àti lára àwon tí ó figa gbága ní BBNaija rí ni Bisola Aiyeola ...
Read More »Awoyemi Bamimore Comments Off on Ènìyàn tí ó n gbé inú èkú láti ojó yìí tí a kò mò tí ó n jé lágbájá, àwòrán è rèé.
Okùnrin kan tí ó n gbé inú èkú fohún bí egúngún tí a mò sí lágbájá ni àwòrán hàn ní ìsàlé yí fún ànfààní àwa tí a kò da mò. Gbajúgbajà olórin a kó ni l’ógbón ni Lágbájá àwòrán rè ...
Read More »Omo kékeré àná náà ti dàgbà, àdúrà wa ni wípé kí olórun má pa omo fún olómo. Favour Iwueze ìkan lára àwon omo kékeré ìgbàyan ti setán láti se ìgbéyàwó, kí ire ayò náà kárí.
Read More »Awoyemi Bamimore Comments Off on Oòni ti ìlú ilé-ifè darapò mó àwon mùsùlúmí ilé-ifè láti kírun ní ojó odún iléyà tí a mò sí Eid-el kabir.
Gégé bí a se mò wípé àwon omo léyìn músùlùmí sèsè se àsekágbá odún won ní léyìn tí won ti gba ààwè séyìn léyìn bí osù mejì àti òsè mélòó sèyìn. Oba Adeyeye Enitan Ogunwusi ti darapò mó àwon músúlúmi ...
Read More »Awoyemi Bamimore Comments Off on Arákùnrin kan ni ó na ìyàwó rè, tí ó sì ba àwò ara ré je.
Arákùnrin kan ni a gbó wípé ó na ìyàwó rè tí ó sì dá àpá si lára, ládúrú bí won ti se n kó wa ní èkó lórí bí a se le gbé lókoláya tó. Bí ó tilè jé wípé ...
Read More »Awoyemi Bamimore Comments Off on Odún ìsèsi àgbáyé
Ogúnjó osù kejo (20/8) odoodún ni odún ìsèsi màa ń wáyé káàkiri àgbáyé. Ìlú kòòkan ni ó sì máa ń se odún náà sùgbón àwon ìpínlè Kan wà tí won máa ń se é papò bí ìpínlè Osun. Àjòdún odún ...
Read More »ayangalu Comments Off on Is there a “complete” written copy of the Odu Ifa ?
People often ask me if there is a “complete” written copy of the Odu Ifa. However, within the Odu Ifa it explains that there is no babalawo who knows all of the Odu Ifa because the pages in the Odu ...
Read More »ayangalu Comments Off on Orin isese
Ao bo isese o, ao bo isese olowo o, isese o lao bo o, kawa to borisa o, BABA mi isese, IYA mi isese, lao bo o, kawa to borisa o, ORI mi isese, IKIN mi isese, lao bo o, ...
Read More »
Ọmọ Oòduà Naija Gist | News From Nigeria | Entertainment gist Nigeria|Networking|News.. Visit for Nigeria breaking news , Nigerian Movies , Naija music , Jobs In Nigeria , Naija News , Nollywood, Gist and more