Home / News From Nigeria / Breaking News (page 150)

Breaking News

No Phones In Kitchen Please

  Do you make calls or receive calls in your kitchen? My name is Dr. Ademola. Just 3 days ago my husband who also is a doctor shared the sad incidents of 6 individuals who were brought into the casualty ...

Read More »

Nìjíríà ìgbà wo ni a ó gba òmínira.

Nìjíríà ńlé sunkún Àwon èèyàn ibè ò ye é rérìn-ín òfò Èrín òfò tí won rò pé ti ìdùnú ní se Nìjíríà ìlú tí òmínira rè ti di omi ìnirà Atún ti wálé Ojó wo ni àwa náà yóò gba ...

Read More »

A DÚPẸ́ OOO GBOGBO ILẸ̀ WA TI DI IBOJÌ

A dúpẹ́ o Ikú ti di tiwa A dúpẹ́ o Àwọn èèyàn wa ò figi da mààlúù mọ́ AK 47 ni wọ́n ń lò A dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọ́run Iṣẹ́ darandaran ti di iṣẹ́ dánràndáràn Èdùmàrè a dúpẹ́ o Ẹ dúró ...

Read More »
dbanj son

Àbíkéyìn gbajúgbajà olórin tí a mò sí D’banj ni a gbó wípé Ó kú sí omi ní àná.

omokùnrin gbajúgbajà olórin tí a mò sí D’banj tí orúko omo náà ń jé Daniel ni a gbó wípé Ó kú sí omi ní àná tí a mò sí ojó kerìnlélógún osù kerin odún yii. Kí olúwa kí ó bá ...

Read More »

Rántí òla

Ohun tí a se lónìí Ìtàn ni b’ódòla Lisabi Agbongbo Àkàlà Fi ìwà akin gba gbogbo Ègbá kalè L’óko erú Olóòyó Ògèdèngbé ń be nínú ìwé ìtàn ìjeshà Asíwájú rere ní se Moremi obìnrinkùnrin n’ífè ńkó, a kò le gbàgbé ...

Read More »

Ọ̀YÀYÀ (CHEERFULNESS)

Èro àlọ, Ẹ wá gbọ́, èrò àbọ̀, Ẹ wá tẹ́tí sími Oògùn ọlá tí mo ṣẹ̀ṣẹ̀ rí ní mo fẹ́ wí f’áyé Oògùn ọrọ̀ tí mo ṣẹ̀ṣẹ̀ gbà ní mo fẹ́ ròyìn Àtọjọ́ mo ti dáyé, Àtọjọ́ mo ti ń ...

Read More »
dbanj son

Dbanj Loses 1 Year Old Son Daniel

In an exceedingly sad turn of events, Singer Dbanj and his wife Lineo Didi Kilgrow have today lost their son Daniel. Daniel Oyebanjo III who turned one in May is said to have died after drowning at Dbanj’s ikoyi residence ...

Read More »

Ìgbà èdá

Ìgbà kò lo bí òréré Ayé kò lo bí òpá ìbon, Ìgbà kan ńlo Ìgbà kan ńbo Kí elédùmarè jé kí á n’ígbà tó dára n’ílé ayé wa Ìgbà kan ni ogún náírà yí níyì púpò Sùgbón nísìnín Ó ti ...

Read More »
musa

Ahmed Musa ti mu Nìjíríà rérìn-ín ayò léèkan sí.

Gégé bí a ti mò wípé eré bóòlù ife àgbáyé ńlo lówó. Ahmed Musa tí Ó jé òkan Lára àwon omo agbábòòlú Nìjíríà ti gbá bóòlù méjì òtòtò wo ilé àwon alátakò won tí a mò sí ikò Iceland.

Read More »
ifa

Photo news: Ifa is reliable !

Ifa is Light !

Read More »

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb