Home / Art / Àṣà Oòduà / Adarí àgbà ilé ìwòsàn UCH kò ní àrùn Coronavirus mọ́
corona

Adarí àgbà ilé ìwòsàn UCH kò ní àrùn Coronavirus mọ́

Họ́wùú! bí babaláwo bá ń kígbe ẹ̀fọ́rí, kín ni yóó jẹ́ àtubọtán aláìsàn? Kò jẹ́ jẹ́ bẹ́ẹ̀.

Adarí àgbà ilé ìwòsàn ẹ̀kọ́ṣẹ́, UCH Íbàdàn Ọ̀jọ̀gbọ́n Abiodun Otegbayo ti yiijẹ o, kò ní àrùn Coronavirus mọ́ lẹ́yìn tó sàyẹ̀wò àrùn náà nígbà kejì.

Ṣaájú ní Otegbayo ti kọ́ sàyẹ̀wò, tí èsì àyẹ̀wò ọ̀hún sì fi hàn pé ó ti fara káásá àrùn náà, èyí tó mú kó ya ara rẹ̀ sọ́tọ̀ fún ìtọ́jú.

Ṣùgbọ́n lẹ́yìn tó lo ọjọ́ mẹ́jọ ní ìyàsọ́tọ̀ ọ̀hún ló sàyẹ̀wò lẹ́ẹ̀kejì, tí èsì sì fi hàn pé kò ní àrùn náà lára mọ́.

Agbẹnusọ ilé ìwòsàn ẹ̀kọ́ṣẹ́ UCH, Toye Akinrinlola ló fi ọ̀rọ̀ náà léde fún àwọn akọ̀rọ̀yìn lọ́jọ́bọ

Fẹ́mi Akínṣọlá

About ayangalu

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

History 101: What it takes to be a MENTALLY ENSLAVED FOOL in Your ancestral Land.

History 101: What it takes to be a MENTALLY ENSLAVED Harlequin in Your ancestral Land.

The quote for today is a page from Toyin Falola’s book, ‘Yoruba Warlords of the 19th Century’. To a lot of Yoruba Muslims. Islam means servitude to Usman Dan Fodio’s estate at Sokoto. They indulge in the same idiocy that led to the fall of the great Hausa civilization. Many Yoruba Muslims from Oyo are a dangerously brainwashed set of people that would pose future danger for the preservation of Yorubaland like their ancestors who pledged allegiance to Ilorin and ...