Home / Art / Àṣà Oòduà / Ogún ènìyàn jàjà bọ́ lọ́wọ́ coronavirus
contain corona virus

Ogún ènìyàn jàjà bọ́ lọ́wọ́ coronavirus

Ogún ènìyàn jàjà bọ́ lọ́wọ́ coronavirus
Ìròyìn láti ọwọ́ Yínká Àlàbí


Ni ipinle Eko ni ori ti ko ogun eniyan yo ni ile iwosan ti won ti n toju awon ti kokoro Covid-19 n ba ja.


Bi o tile je pe won ni ko si oogun kan gbogi fun aisan naa sugbon Eledua n fun ipinle Eko se lati ni aseyori lori itoju awon alaisan naa. Ti a ko ba gbagbe, arakunrin omo orileede Italy ni o koko gba iwosan naa ki awon meta miiran, marun-un miiran ki mokanla to kun-un ni oni ojo keji, osu kerin odun ti a wa yii.


Ijoba apapo, ipinle ati ibile pelu ajo NCDC ni ki awon eniyan ma se dawo imototo duro ki onikaluku si gbe ile re fun igba die ki arun buruku naa le kase nile patapata.

About ayangalu

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

History 101: What it takes to be a MENTALLY ENSLAVED FOOL in Your ancestral Land.

History 101: What it takes to be a MENTALLY ENSLAVED Harlequin in Your ancestral Land.

The quote for today is a page from Toyin Falola’s book, ‘Yoruba Warlords of the 19th Century’. To a lot of Yoruba Muslims. Islam means servitude to Usman Dan Fodio’s estate at Sokoto. They indulge in the same idiocy that led to the fall of the great Hausa civilization. Many Yoruba Muslims from Oyo are a dangerously brainwashed set of people that would pose future danger for the preservation of Yorubaland like their ancestors who pledged allegiance to Ilorin and ...