Home / Art / Àṣà Oòduà / Akékòó ilé -èkó Nwafor Orizu College Nsugbe ni àwon omo egbé òkùnkùn yin ìbon pa. 
nocen

Akékòó ilé -èkó Nwafor Orizu College Nsugbe ni àwon omo egbé òkùnkùn yin ìbon pa. 

  Léyìn àrídájú tó ji-n-gí-ri, mo le f’owó s’òyà pé pé ilé-èkó Nwafor Orizu College of Education Nsugbe ti pàdánù tí ó pò .
  Arákùnrin Mr Osaji Charles, tí ó jé Mr NASELS télè (2013/2014 session), ni won yín ìbon fún tí a kò sì mo eni tí ó yin ìbon náà níbi tí kò jìnà sí “ota  Queen “. Mr Don Charles, bí ó se dáhùn lórí èro ayélujàra (facebook), ó ye kí ó parí ìdánwò àsekágbá ti eka-èkó rè ní ojó etì ojó ketàlélógún osù keje odún tí a wà yí (21st of July) tí ó sì ye kí o se ayeye ìkékòó jáde ní ojó karùndínlógbòn (25th) nígbà tí ó ti parí gbogbo ohun míràn tí ó ye kí ó se.
A bá gbogbo ìdílé Osaji kédùn, pèlú àwon akékòó eka-èkó èdè gèésì English department NOCEN, pèlú gbogbo àwon ilé-èkó t’ókùn ní agbègbè náà. Àkókò yí ni inú wa bàjé púpò .
 Sùn -un re oooo

Continue after the page break for English Version

About admin

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

policeman

Ọ̀gbẹ́ni Olaoye déèdé pòórá nílé ìtura kan nílùú Akure

Fẹ́mi Akínṣọlá Ádùrá tí a máa ń ṣe ni pé kí á má rin àrin f’ẹsẹ̀sí.Mọ̀lẹ́bí ọkùnrin kan, Ògbẹ́ni Olaoye Olatunde, tó jẹ́ igbákejì ọ̀gá àgbà ilé ẹ̀kọ́ girama kan nílùú Ọwọ ti ké gbàjarè pé ọkùnrin náà di àwárítì lẹ́yìn tó lọ fún idanilẹkọ ní ilé ìtura Sunview nílùú Akure. Iyawo arakunrin naa salaye rẹ pe, ni ọjọ kẹrinlelogun oṣu Kẹjọ, ọdun 2025, ni ọkọ rẹ dagbere pe ohun n lọ fun idanilekọ kan n’iluu Akure, eyi ti wọn ...