Home / Art / Àṣà Oòduà / “Gbajue paraku ni Dokita Akintunde Ayeni” -Onibara Yem-Kem lo so bee
Akintunde Ayeni

“Gbajue paraku ni Dokita Akintunde Ayeni” -Onibara Yem-Kem lo so bee

Arabirin Bamidele Ademola-Olateju lo gbe atejade kan sori ero FACEBOOK re nipa alase Yem-Kem International, Dokita Akintunde Ayeni. O ni gbajue paraku ni  maanu naa. Ohun ti arabirin Bamidele tun wa fi kun un ni wi pe,  Dokita Akintunde ti wa ninu wahala nla bayii.

Onibara Yem-Kem to n gbe loke okun yii tun so wi pe, owo ti dokita isegun ibile naa ni ati awon alagbara to feyinti lo je ki won ri ina iroyin wahala to ko si naa pamole patapata ti ko fi lu seti awon omo araye.

 
 E je ka tesiwaju lati ka alaye arabirin naa bo se ko lede geesi:

About admin

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

“Ìyálóde, Eléékò & The Heavenly Companions: Discover the Mysterious Classes of Egbe in Yoruba Tradition”

Classes of Egbe (Heavenly Mate of Every Human) Also known as Alaragbo in some areas of Yoruba land, Egbe is generally more associated with children than with adults according to Eji-Ogbe. Based on the character traits of human on Earth, the Yoruba have classified Egbe into different categories. Ìyálóde Ìyálóde is regarded as the leader of Egbe on Earth. Leadership quality is most evident characteristic of this class of Egbe. Going by the name, it may appear that only females ...