Home / Art / Àṣà Oòduà / Igbo pàdé calabar, àwòrán kí won tó se ìgbéyàwó bí okùnrin náà se fi owó kó ìdí arábìnrin náà.

Igbo pàdé calabar, àwòrán kí won tó se ìgbéyàwó bí okùnrin náà se fi owó kó ìdí arábìnrin náà.

Àwòrán èyí kí ó tó di ojó ìgbéyàwó ti arákùnrin Igbo tí a mò sí Ofor, tí ó ti se tán láti fé aya àfésónà rè Witney tí ó jé Calabar ní ojó etì, ojó kejìdínlógún osù kokànlá odún yí (18/11/2017).

Oko tí ojú rè ti wà lónà ní láti gbá ìdí ìyàwó rè mú, èyí fi hàn wípé okùnrin yí ti to ara rè sí okùnrin àkókó nínú ayé obìnrin yí.

A ki yí tokotaya tí ó n bò lónà .

About Awoyemi Bamimore

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

Omisore

Àwàdà kẹrí-Kẹrì ni àwọn kọmití tó ní mi ò lè díje du ipò gómìnà APC ni 2026 n ṣe – Omisore

Yínká Àlàbí Awọn kọmiti to n ṣe àyẹ̀wò awọn oludije du ipo gomina labẹ ẹgbẹ́ oselu APC ti ja igbakeji gomina tẹlẹ ni ipinle Osun, Alagba Iyiola Omisore ati awọn mẹfa miiran.Wọn ni iwe wọn ko pe lati dije du ipo gomina ipinlẹ naa. Awọn mẹfẹẹfa to ku naa ni – Babatunde Oralusi, Oyedotun Babayemi, Dr. Akin Ogunbiyi, Benedict Alabi, Adegoke Rasheed Okiki, ati Senator Babajide Omoworare.Iyiola Omisore ni awada Kẹri-Kẹri ni awọn kọmiti naa n se nitori ti wọn ...